554
ÌWÉ TI MMNÌ RÍ MÍRÀN TI JÉSÙ KRÍSTÌ

ÌWÉ TI MỌ́MỌ́NÌmedia.ldscdn.org/pdf/lds-scriptures/book-of-mormon/book-of-mormon-34406-yor.pdfx àwonâlélñsí,àtitíóríkederetíósìyàtÿtímotúnmõibånígbàtí

  • Upload
    others

  • View
    1

  • Download
    0

Embed Size (px)

Citation preview

  • ÌWÉ TI

    MỌ́MỌ́NÌ Ẹ̀RÍ MÍRÀN TI JÉSÙ KRÍSTÌ

  • Ìwéti

    MõmõnìÑRÍ MÍRÀN

    TI

    JÉSÙ KRÍSTÌ

  • Ẹ̀tọ́ láti ṣe ẹ̀dà íwé © 2007 Láti ọwọ́

    Intellectual Reserve, Inc. І́lú-ńlá Salt Lake City, Utah, ilẹ̀ Améríkà

    Gbogbo ẹ̀tọ́ ni a fi pamọ́Printed in the United States of America 6/2009

    19932007Translation of the Book of Mormon

    YorubaISBN 978-1-59297-612-6  (Hardcover 35606 779) ISBN 978-1-59297-613-3 (Paperback 35607 779)

  • Ìwé ti MõmõnìÌWÉ ÌTÀN TÍ A KÜ LÁTI

    ÜWÕ MÕMÕNÌ SÍ ÓRÍ

    ÀWÜN ÀWO TÍ A MÚ KÚRÒ

    NÍNÚ ÀWÜN ÀWO TI NÍFÁÌ

    Nítorínâ, ó jå ìkékúrú ìwé ìrántí ti àwün ènìyàn Nífáì, àti pñlú tiàwün ará Lámánì — A kü õ sí àwün ará Lámánì, tí wõn jå ìyókùidile Isráålì; áti pñlú sí àwün Jû àti Kèfèrí — A kü õ nípa ÿnà àãä, àtipñlú nípasñ ñmí ìsütålñ àti ti ìfihàn — A kü õ a sì fi èdídì dì í, a sì paá mõ sí Olúwa, kí á má bà lè run wõn — Láti jáde wá nípasñ ñbùnàti agbára Ülõrun sí ìtumÿ ti èyí nâ — A fi èdídì dì í nípa üwõMórónì, a sì pa á mõ sí Olúwa, láti jáde wá nígbàtí àkókò bá tó nípasñKèfèrí — Ìtumÿ ti èyí nâ nípasñ ñbùn Ülõrun.

    Ìkékúrú tí a mú láti inú Ìwé Étérì pñlú, èyí tí ó jå ìwé ìrántíàwün ènìyàn Járådì, àwün tí a túká ní àkókò tí Olúwa da èdè àwünènìyan nâ rú, nígbàtí wõn nkõ ilé ìãõ gíga láti dé ÿrun — Èyí jå látifi hàn sí ìyókù ará ilé Isráålì àwün ohun nlá èyí tí Olúwa ti ãe fúnàwün bàbá wün; àti pé kí wõn lè mõ àwün májñmú Olúwa, pé kí ao má sü wõn kuro títí láé — Àti pñlú sí yíyí lõkàn padà Jû àti Kèfèrípé Jésù ni Krístì, Ülõrun Ayérayé, tí nfi ara rñ hàn sí gbogboorílñ-èdè — Àti nísisìyí, bí àbùkù bá wà, wõn jå àãìãe àwün ènìyàn;nítorínâ, ä máãe dá àwün ohun Ülõrun låbi, kí a lè rí yín láìlábàwõnní ìtå ìdájõ Krístì.

    Ìyírÿpadà sí èdè míràn tí a kõ ãe láti àwün àwo sí G∑sìláti üwõ Joseph Smith, KékeréÃíãe èkíní ní G∑sì ni a tñ ní ìlú

    Palmyra, New York, ilñ Amåríkà, ní üdún 1830

    A tñ å láti üwõÍjü Jésù Krístì ti Àwün Ènìyàn

    Mímõ ti Üjõ-Ìkähìnìlú-nlá Salt Lake, Utah, ilñ Amåríkà

  • v

    ŸRŸ ÀSÜÃÂJÚ

    Ìwé ti Mõmõnì jå àpapÿ ìwé mímõ tí a lè fi wé Bíbélì. Ó jå ìwéìrántí ìbáló Ülõrun pñlú àwün olùgbé ilñ Amåríkà lápapÿ níatijõ, ó sì ní ñkún ìhìn-rere àìlópin nínú.

    A kü ìwé nâ látí üwõ ÿpÿlüpÿ àwün wòlî àtijõ nípasñ ñmí ìsütålñàti ìfihàn. Àwün ÿrÿ wün, tí a kü sórí àwün àwo wúrà, ni wòlî-òpìtàn kan tí á n pe orúkü rñ ní Mõmõnì tún wí tí ó sì ké kúrú. Ìwéìrántí nâ fún ni ní ìwé ìtàn ÿlàjú nlá méjì. Ÿkan wá láti Jerúsálåmùní ägbñta üdún kí á tó bí Krístì, låhìnnâ tí wõn pín sí orílñ-èdè méjì,tí a mÿ sí àwün ará Nífáì àti àwün ará Lámánì. Òmíràn ti wá síwájúnígbà tí Olúwa da ahõn rú ní Ilé ìãõ gíga Bábélì. Ñyà yí ni a mÿ síàwün ará Járådì. Låhìn ägb∑gbñrún üdún, gbogbo wün ni a parunàfi àwün ará Lámánì, wõn sì wà ní ârin àwün bàbá-≥lá àwün aráIndíà ti ilñ Amåríkà.

    Ìãñlñ àãekagbá tí a kü sínú Ìwé ti Mõmõnì ni iãå ìránãå ti JésùKrístì Olúwa ãe fúnra rñ lârín àwün ará Nífáì ní kété låhìn àjínderñ. Ó mú àwün ñkõ ìhìn-rere jáde, ó fi ìlànà ìgbàlà lélñ låsäsä, ó sì süfún àwün ènìyàn ohun tí wün kò lè ãàìãe láti rí àlâfíà gbà ní ayé yíàti ìgbàlà ayérayé ní ayé tí mbÿ.

    Låhìn tí Mõmõnì parí àwün ìkÿwé rñ, ó jÿwõ ìwé ìtàn nâ fúnümü rñ Mórónì, äni tí ó fi àwün ÿrÿ tirñ díñ kún un tí ó sì gbé àwünàwo nâ pamõ ní òkè Kùmórà. Ní üjÿ kükànlélógún oãù käsán,üdún 1823, Mórónì kannâ, ñdá tí a ti ãe lógo tí ó sì ti jínde nígbànâ,farahàn sí Wòlî Joseph Smith ó sì kõ ü ní ñkõ nípa ti ìwé ìrántí tiàtijõ nâ àti ìyírÿpadà rñ tí a ti pinnu sí èdè G∑sì.

    Nígbàtí àkókò tó ó jÿwõ àwün àwo nâ fun Joseph Smith, äni tíó yí ÿrÿ wün padà nípasñ ñbùn àti agbára Ülõrun. Ìwé ìrántí nâ ni awá tñ báyî ní ÿpÿlüpÿ èdè gågå bí ñrí titun àti àfikún pé Jésù Krístìni Ümü Ülõrun alâyè, àti kí gbogbo äni tí ó bá wá sõdÿ rñ, tí ó bá sìgbõran sí àwün òfin àti ìlànà ìhìn-rere rñ lè rí ìgbàlà.

    Nípa ìwé ìrántí yí Wòlî Joseph Smith wí pé: “Mo sü fún àwünarákùnrin pé Ìwé ti Mõmõnì ni ó pé jù ìwé èyíkéyí lü lórí ilñ ayé, ósì jå òkúta-ìãíkà ìsìn wa, ènìyàn yíò sì súnmõ Ülõrun nípa bíbáàwün ìlànà rñ gbé, ju ti ìwé èyíkéyí míràn.”

    Ní àfikún sí Joseph Smith, Olúwa pèsè àwün mõkànlá mírànláti rí àwün àwo wúrà nâ tìkaláawün àti láti jä akanãe älårî péÌwé ti Mõmõnì jä òtítõ ati ohun ti Ÿrun. Àwün ñrí wün tí a kü ni afi pñlú níhìn yî gågåbî “Ñrí Àwün Älåri Måta” àti “Ñrí ÀwünÄlåri Måjü.”

    A pe gbogbo ènìyàn níbigbogbo láti ka Ìwé ti Mõmõnì, láti rò níükàn wün ìhìn tí ó wà nínú rñ, nígbànâ kí wõn sì bèrè lõwõ Ülõrun,Bàbá Ayérayé, ní orúkü Krístì bí ìwé nâ bá jå òtítõ. Àwün tí ó bá

  • vi

    lépa ipa ÿnà yí tí wõn sì bèrè ní ìgbàgbõ yíò jèrè ñrí pé ó jå òtítõàti ti ÿrun nípasñ agbára Ñmí Mímõ. (Wo Mórónì 10:3–5.)

    Àwün tí ó bá gba ñrí ti õrun yí láti üwõ Ñmí Mímõ yíò wá mÿpñlú nípa agbára kannâ pé Jésù Krístì ni Olùgbàlà ayé, pé JosephSmith ni olùfihàn àti wòlî rñ ní awün üjõ ìkähìn yî, àti pé Ìjü JésùKrístì ti Àwün Ènìyàn Mímõ ti üjõ Ìkähìn ni ìjüba Olúwa tí a túngbé kalñ l∑kan sí i lórí ilñ ayé, ní ìmúrasílñ fun bíbÿ äläkejì tiMessia.

  • vii

    ÑRÍ ÀWÜN ÄLÅRI MÅTA

    A få kí ó jå mímÿ sí gbogbo orílñ-èdè, ìbátan, èdè, àti ènìyàn, sí ÿdÿàwün tí iãå yí yíò wá: Pé àwa, nípa ôre-ÿfå Ülõrun Bàbá, àti JésùKrístì Olúwa wa, ti rí àwün àwo èyí tí ó ní ìwé ìrántí yí nínú, èyí tíó jå ìwé ìrántí àwün ènìyàn Nífáì, àti pñlú ti àwün ará Lámánì,àwün arákùnrin wün, àti pñlú ti àwün ènìyan Járådì, tí wõn wá látiilé ìãõ gíga èyí tí a ti sÿ nípa rä. A sì mÿ pñlú pé a ti yí wün padà síèdè míràn nípa ñbùn àti agbára Ülõrun, nítorí ohùn rñ ti sü õ fúnwa; nítorí-èyi a mÿ dájú pé òtítõ ni iãå nâ. A sì jårî pñlú pé a ti ríàwün ìfín èyí tí ó wà lórí àwün àwo nâ; a sì ti fi wõn hàn fún wanípasñ agbára Ülõrun, kì í sì ãe tí ènìyàn. A sì sü pñlú àwün ÿrÿ ìwàpñlå, pé angålì Ülõrun kan sõkalñ láti ÿrun, ó sì mú wün wá ó sìgbé wün kalñ níwájú wa, tí a sì kíyèsî tí a sì rí àwün àwo nâ, àtiàwün ìfín ti orí rñ; a sì mÿ pé nípa ôre-ÿfå Ülõrun Bàbá, àti JésùKrístì Olúwa wa, ni àwa fi kíyèsî tí a sì jårî pé àwün ohun wÿnyí jåòtítõ. Ó sì jå ìyanu ní ojú wa. Bíótilñrib∑, ohùn Olúwa pàãä fún wapé kí á jårî rñ; nítorí-èyi, láti ní ìgbõran sí àwün àãä Ülõrun, a jårîàwün ohun wÿnyí. A sì mÿ pé bí a bá jå olódodo nínú Krístì, àwayíò gba aãü wa kúrò ní ñjñ gbogbo ènìyàn, a ó sì wa láìlábàwõnníwájú ìtå ìdájõ Krístì, a ó sì gbé pñlú rñ títí ayérayé ní ÿrun. Ki ülánâ sì jå sí Bàbá, àti sí Ümü, àti sí Ñmí Mímõ, èyí tí íãe Ülõrun kan.Àmín.

    Oliver CowderyDavid WhitmerMartin Harris

  • viii

    ÑRÍ ÀWÜN ÄLÅRI MÅJÜ

    A få kí ó jå mímÿ sí gbogbo orílñ-èdè, ìbátan, èdè, àti ènìyàn, si ÿdÿàwün tí iãå yí yíò wá: Pé Joseph Smith, Kékeré, olùtúmÿ-èdè iãå yí,ti fi àwün àwo èyí tí a ti sÿrÿ nípa rñ hàn wá, èyí tí ó dàbí wúrà;gbogbo àwün ojú-ewé tí Smith tí a sü yí ti tumü ni a ti dìmú pñlúüwõ wa; a sì rí àwün ìfín ti orí rñ pñlú, gbogbo èyí tí ó ní ìfarahàniãå àtijõ, àti ügbõn iãå tí ó ãõwõn. Èyí ni a sì jårî pñlú àwün ÿrÿ ìwàpñlå, pé Smith tí a sü nâ ti fi hàn wá, nítorí a ti rí i a sì ti gbé e yñwò,a sì mÿ dájú pé Smith tí á sü nâ ti gba àwün àwo èyí tí a ti sÿrÿ níparñ. A sì fi orúkü wa fún gbogbo ayé, láti jårî fún gbogbo ayé ohunèyí tí a ti rí. Àwa kò sì purõ, Ülõrun n jårî rñ.

    Christian Whitmer Hiram PageJacob Whitmer Joseph Smith, ÀgbàPeter Whitmer, Kékeré Hyrum SmithJohn Whitmer Samuel H. Smith

  • ix

    ÑRÍ WÒLÎ JOSEPH SMITH

    Àwün ÿrÿ Wÿlî Joseph Smith fúnrarñ nípa jíjáde wá Ìwé tiMõmõnì ni:

    “Ní àãâlå . . . üjõ kükànlélógún oãù käsán {üdún 1823} . . . Modáwõlé àdúrà àti ñbñ sí Ülõrun Olódùmarè . . . .

    “Nígbà tí mo wà ní ipò pípe Ülõrun, mo rí ìmõlñ kan tí ó ≥tàn wánínú yàrá mi, èyí tí ó sì ≥pÿ si títí tí yàrá nâ fi mõlñ ju ÿsán gangan,låsñkan nâ äni nlá kan fi ara hàn ní ñgbå ibùsùn mi, tí ó dúró níòfúrufú, nítorí äsñ rñ kò kan ilñ.

    “Ó wü ñwù tí ó ãò, tí funfun rñ ni ógo jùlü. Ó funfun ju ohun-kóhun ní ayé tí mo ti rí; nkò sì gbàgbõ pé a lè mú ohunkóhun ní ayéláti funfun kí ó sì kü mÿnà tó b∑. Aãü kò bò àwün üwõ rñ, àti awünapá rñ pñlú, díñ sókè àwün ürùn-üwõ; b∑nâ, pñlú, ni aãü kò boawün àtåläsñ rñ, bí ti äsñ rñ, díñ sókè ürùn äsñ. Orí rñ àti ürùn rñ wàláìbò pñlú. Mo lè sü pé kò wü aãü míràn sõrùn àfi ñwù yí, bí ó ãe ãísílñ, tí mo lè rí àyà rñ.

    “Kì í ãe ñwù rñ nìkan ni ó funfun lõpÿlüpÿ, ãùgbõn gbogbo ararñ lógo küjá àpèjúwe, ìrísí rñ sì yü bí mànàmáná. Yàrá nâ mõlñréküjá, ãùgbõn ko mõlñ gan-an tó bí àyíká ara rñ. Nígbàtí mo wò ól∑kíní, ñrù bà mí; ãùgbün ñrù nâ fi mí sílñ láìpå.

    “Ó pè mí ní orúkü mi, ó sì wí fún mi pé òun ni ìránãå tí a rán látiÿdÿ Ülõrun sí mi, àti pé orúkü òun ni Mórónì; pé Ülõrun ní iãå fúnmi láti ãe; àti pé orúkü mi ni a ó ní fún rere àti búburú lârín gbogboorílñ-èdè, ìbátan, àti èdè, tàbí pé a ó sü ü ní rere àti búburú lâríngbogbo ènìyàn.

    “Ó ní iwé kan wà tí a filélñ, tí a kü sórí àwün àwo wúrà, tí ó fúnni ní ìwé ìtàn àwün olùgbé ti tìãájú ti ìpínlñ-ayé yí, àti orísun ibi tíwõn ti sun jáde. Ó sü pñlú pé ñkún Ìhìn-rere àilòpin nì ni a ní nínúrñ, bí Olùgbàlà ti fi sílñ fún àwün olùgbé àtijõ;

    “Pälú-pñlù, pé Òkúta méjì wà nínú üpõn fàdákà — àwün òkútawÿnyí, tí a so mõ ìgbàya kan, sì ni ohun tí à npè ní Úrímù àtiTúmímù — tí a fi lélñ pñlú àwün àwo nâ; ìní àti ìlò àwün òkútawÿnyí ni ohun tí à npè ní Aríran ní àwün ìgbà àtijõ tàbi ìgbà ìãâjú;àti pé Ülõrun ti pèsè wün fún ète ìtúmÿ iwé nâ.

    * * * * * * *

    “Ñwñ, ó sü fún mi, pé nígbà tí mo bá gba àwün àwo wünnì nípaèyí tí ó ti sü — nítorí àkókò tí a ó gbà wõn ni a kò ì tí ì múãä — Èmikò gbódÿ fi wõn hàn sí änikåni; b∑ni ìgbàyà nâ pñlú Úrímù àtiTúmímù nâ; àfi sí àwün wünnì nìkan tí a ó pàãä fún mi láti fi hàn;bí mo bá ãe é a ó pa mí run. Ní àkókò tí ó n sÿrÿ pñlú mi nípa àwünàwo nâ, a ãí ìran nâ sínú iyè mi, tí ó jå wípé mo lè rí ibi tí a fi àwün

  • x

    àwo nâ lélñ sí, àti tí ó rí kedere tí ó sì yàtÿ tí mo tún mõ ibå nígbà tímo bñ å wò.

    “Låhìn ÿrÿ yí, mo rí ìmõlñ inú yàrá nâ tí ó bñrñ sí nkó jü lõgán níàyíká ara äni tí ó ti n bá mi sÿrÿ, ó sì n ãe bå ñ lü, títí tí yàrá nâ túnpadà ãókùnkùn, àfi ní àyíká rñ gan, nígbànâ ní mo rí i lójúkannâ, bío ãe rí, ÿnà kan tí ó ãí târà sókè sí ÿrun, ó sì gòkè lü títí ó fi farasinpátápátá, yàrá nâ ni a sì fi sílñ bí ó ãe wà kí ó tó di pé ìmõlñ ÿrun yíãe ìfarahàn rñ.

    “Mo sùn sílñ mÿ nronú lórí ohun àrà tí ó ãälñ, ní ìyanu nlá síohun tí ìránãå àrà-ÿtÿ yí ti sü fún mi; nígbàtí, ní ârín ìãârò mi, modêdé ríi tí yàrá mi tún bñrñsí mõlñ, lójúkannâ, ìránãå ÿrun kannâ sìtún ti wà ní ñgbå ibùsùn mi.

    “Ó bñrñ, ó tún nsü àwün ohun kannâ èyí tí ó ti sü ní àbñwò àkõkõrñ, láìsí ìyàtÿ kankan; låhin eyi, o wí fún mi nípa ìdájõ nlá tí ómbÿwá sórí ayé, pñlú ìsüdahóró nlá nípa ìyàn, idà, àti àjàkálñ-àrùn; àti pé àwün ìdájõ tí mbáni nínú jå wÿnyí yíò wá sí ayé níìran yí. Låhìn tí ó ti sü àwün ohun wÿnyí, ó tún gòkè lü bí ó ti ãe níàkõkõ.

    “Ní àsìkò yí, àwün ohun tí a tñ mõ ükàn mi jinlñ gan-an, tí ôrun tisá kúrò lójú mi, mo sì dùbúlñ pñlú ní ìyanu sí ohun tí mo tí rí àti tímo gbõ. Ãùgbõn kí ni ìyàlånu mi nígbàtí mo tún kíyèsî ìránãåkannâ ní ñgbå ibùsùn mi, mo sì gbõ ü tí ó tún kà tàbí tún sü fún miñwñ àwün ohun kannâ bí ti àtñhìnwá; ó sì fún mi ní ìkìlÿ, ó n sü fúnmi pé Sátánì yíò gbìyànjú láti dán mi wò (nítorí ti ipò aláìní tí ìdílébàbá mi wà), láti gba àwün àwo nâ fún kíkó ürÿ jü. Èyí ni ó dá milåkun sí, ó wí pé èmi kò gbõdÿ ní ìdí míràn lõkàn ní gbígba àwünàwo bíkòãe láti yin Ülõrun lógo, n kò sì gbõdÿ jå kí ìdí míràn ní ipalórí mi ju ti kíkõ ìjüba Rñ; bí b∑kõ èmi kò lè rí wün gbà.

    “Låhìn àbñwò äl∑kåta yí, ó tún gòkè lü sí ÿrun bí ti tålñ, a sì tún fimí sílñ láti ro àjèjì ohun tí mo ãñãñ ní ìrírí; nígbàtí ó fårñ jå gbàrà tíìránãå ÿrun yí n gòkè lü ní ìgbà ñkåta, àkùkõ kü, mo sì rí i pé üjõ tinsúnmõ, ó jå pé àwün ÿrÿ wa ti gba gbogbo òru üjõ nâ.

    “Láìpå, låhìn nâ mo dìde kúrò ní ibùsùn mi, bí ti àtñhinwá, mo sìlü ãe àwün iãå ôjõ tí a kò lè ãe aláìãe; ãùgbõn, bí mo ti ngbìyànjú látiãiãå bí ti àwün ìgbà míràn, mo rí i pé agbára mi ti lü tán tí ó mú miláìlåãñ ohun kánkán. Bábà mi, äni tí o nsiãå pñlú mi, rí i pe ohunkan nãe mí, ó si wí fún mi kí n lü sí ilé. Mo bñrñ pñlú èrò lílü sí ilé;ãùgbõn, bí mo ti ngbìyànjú láti dá ügbà küjá kúrò ní pápá èyí tí awà, agbára mi kùnà pátápátá, mo sì ãubú lulñ láìní ìrànlüwõ, fúnìgbà diñ nkò sì mõ ohunkóhun rárá.

    “Ohun èkíní ti mo rántí ni ohùn kan tí ó bá mi sÿrÿ, tí ó n pè míni orúkü. Mo wo òkè, mo sì kíyèsî ìránãå kannâ tí ó dúró lókè sórími, tí ìmõlñ yí i ká bí ti tålñ. Ó sì tún rò fún mi gbogbo ohun tí ó ti

  • xi

    ròhìn fún mi ní òru ti ìãâjú, ó sì pàãä fún mi láti lü bá bàbá mi kí n sìsü fún un nípa ìran àti àwün àãä èyí tí mo ti gbà.

    “Mo gbõran; mo padà sõdÿ bàbá mi ní pápá, mo sì ro gbogboÿrÿ nâ fún un. Ó dá mi lóhùn pé ó jå ti Ülõrun, ó sì sü fún mi láti lüãe bí ìránãå nâ ti pàãä. Mo kúrò ní pápá nâ, mo sì lü sí ibi tí ìránãånâ sü fún mi pé a fi àwün àwo nâ lélñ sí; nítorí ti dídáãáká ìran èyítí mo ti ní nípa rñ, mo mõ ibñ lójúkannâ tí mo dé ibñ.

    “Nítòsí ìletò Manchester, ní ìbílñ Ontario, ní ìpínlñ New York, niòkè gíga kan dúró, ó sì ga ju èyíkéyi ní agbègbè nâ lü. Ní apáìwÿ-oòrùn òkè yí, tí ko jìnà sí òkè lábå òkúta kan tí ó tóbi, ni àwünàwo nâ wà, tí a fi lélñ nínú àpótí òkúta kan. Òkúta yí nípün ó sì ríroboto ní ârín apá òkè, ó sì tínrín níhà etêtí, tí apá ârín rñ ãe é rí látiòkè, ãùgbõn etêtí rñ yíká ni erùpñ bò.

    “Låhìn tí mo ti mú erùpñ nâ kuro, mo rí igi kan tí ó lè gbé nkansókè, èyí tí mo tì bü abå etêtí òkúta nâ, pñlú agbára díñ mo sì gbé esókè. Mo wo inú rñ, níbñ nítôtõ ni mo sì kíyèsî àwün àwo nâ,Úrímù àti Túmímù, àti ìgbàyà, bí ìránãå nâ ti lâ lås∑sä. Àpótí èyí tíwõn wà nínú rñ ni a ãe nípa kíkó àwün òkúta jü sínú irú amÿ lílekan. Ní ìsàlñ àpótí nâ ni a kó òkúta méjì níbûbú àpótí nâ, ní oríàwün òkúta wÿnyí ni àwün àwo àti àwün ohun míràn wà.

    “Mo gbìyànjú láti gbé wün jáde, ãùgbõn ìránãå nâ dá mí låkun, ósì tún wí fún mi pé àkókò gbígbé wün jáde wá kò ì tí ì dé, b∑ni kò nídé, títí üdún mårin láti àkókò nâ; ãùgbõn ó sü fún mi pé kí n wá síibñ ní üdún kan g∑ láti ìgbà nâ, àti pé òun yíò pàdé mi níbñ, àti pékí èmi máa ãe b∑ títí àkókò nâ yíò dé fún gbígba àwün àwo nâ.

    “B∑gågå, bí a ãe pàãä fún mi, mo nlü ní òpin üdún kπkan, ní ìgbàkπkan ni mo sì nrí ìránãå kannâ níbñ, tí mo sì ngba ñkõ àti òye lõwõrñ ní ÿkπkan àwün ÿrÿ àjüsü wa, nípa ohun tí Olúwa yíò ãe, àtibáwo àti ní ÿnà wo ni a ó fi ãe àkóso ìjüba Rñ ní àwün üjõ ìkähìn.

    * * * * * * *“Níkähìn, àkókò de fún gbígba àwün àwo nâ, Úrímù àti

    Túmímù, àti ìgbàyà nâ. Ní üjõ kejìlélógún oãù kåsan, üdún 1827, bímo ãe lü bí ti àtñhìnwá ní òpin üdún míràn sí ibi tí a fi wõn lélñ sí,ìránãå ÿrun kannâ gbé wün fún mi pñlú àãä yí: Pé kí èmi kí ó tõjúwün; pé bí èmi bá jå kí wõn lü láìbìkítà, tàbí nípa àìfiyèsí tèmi, a óké mí kúrò; ãùgbõn pé bí èmi bá lo gbogbo ìyànjú mi láti pa wõnmõ, títí òun, ìránãå nâ, yíò padà wá fún wün, a ó dábò bò wõn.

    “Láìpå ni mo rí ìdí tí mo ti fi gba írú àãä líle láti pa wõn mõ, àtiìdí tí ìránãå nâ fi sü pé nígbà tí èmi bá ti ãe ohun tí a få lõwõ mi, òunyíò padà wá fún wün. Nítorí kò på tí àwün ènìyàn mÿ pé mo níwün, tí wõn nlo ìgbìyànjú tí ó lágbára jùlü láti gbà wÿn lõwõ mi.Gbogbo àrékérekè tí a lè dõgbõn ni wõn lò fún èté nâ. Inúnibíni nâ

  • xii

    wá korò, ó sì roro ju tålñ, ÿpÿlüpÿ ni ó sì nãõra títí láti gbà wõnlõwõ mi bí ó bá ãeéãe. Ãùgbõn nípasñ ìmÿ Ülõrun, wõn wà láìléwuní üwõ mi, titi nwün o fi ran mi lõwõ láti ãe àãeyürí àwün ohun ti afå láti õwõ mi. Nígbàtí ìránãå nâ padà wá fún wün, gågåbí a ti ãeètò rñ, mo gbé wün fún un; wõn sì wà ní ìpamõ rñ títí üjõ yí, tí n ãeüjõ kejì oãù karún, üdún 1838.”

    Fún ìwé ìrántí ní kíkún, wo Joseph Smith — Ìwé Ìtàn, nínú PerlìOlówó Iyebíye, àti Ìwé Ìtàn ti Ìjü Jésù Krístì ti Àwün Ènìyàn MímõIgba Ìkähìn , apá kíni, orí kíní dé ñkäfà.

    Bayi ni a mú ìwé ìrántí àtijõ jáde wá láti ilñ bí ohùn tí ó nsÿrÿ látiinú eruku wá, tí a sì yí ÿrÿ rä padà sí èdè ìgbà ìsisìyí nípa ñbùn àtiagbára Ülõrun èyítí a ãe ijäri sí nípa ìtänumõ ti Ülõrun, tí a kÿkõ täsí gbogbo ayé ní èdè G∑sì ní üdún 1830 gågå bí The Book ofMormon.

  • xiii

    ÀSÜYÉ NÍ KÚKÚRÚ NÍPA

    Ìwé Ti MõmõnìÌwé ti Mõmõnì jå ìwé ìrántí mímõ ti àwün ènìyàn ilñ Amåríkà àtijõ,a sì fí wün sórí ewé oríãiríãi àwo. Irú oríãiríãi àwo mårin ni a sÿrÿnípa rñ nínú ìwé nâ tìkalârñ:1. Àwün Àwo ti Nífáì, èyítí ó jå oríãi méjì: àwün Àwo Kékeré àti

    àwün Àwo Nlá. Ti tìãâjú ni a lò ní pàtàkì fún àwün nkan ti ñmíàti iãå ìránãå àti àwün ñkõ àwün wòlî, nígbàtí ti ìkähìn kún fúnìwé ìtàn ti ayé ti àwün ènìyàn tí ó kàn (1 Nífáì 9:2–4). Ãùgbõn látiìgbà Mòsíà, àwün àwo nlá nâ ní àwün ohun pàtàkì tí ó jå ti ñmínínú pñlú.

    2. Àwün Àwo ti Mõmõnì, èyí tí ó ní ìkékúrú nípa üwõ Mõmõnì látiinú Àwün Àwo Nlá ti Nífáì, pñlú ÿpÿlüpÿ ìwé àsüyé. Àwün àwowÿnyí ní ìfápåtítí ìwé ìtàn nípa üwõ Mõmõnì àti àwün àfikúnláti üwõ ümü rñ Mórónì.

    3. Àwün Àwo Étérì, èyí tí ó gbé ìwé ìtàn àwün ará Járådì kalñ. Ìwéìrántí yí ni a ké kúrú lati üwõ Mórónì, äni tí ó fi àsüyé tirñ sì ilârín tí ó sì pa ìwé ìrántí nâ pÿ pñlú gbogbo ìwé ìtàn lábå orúkü“Ìwé ti Étérì.”

    4. Àwün Àwo Idä tí àwün ènìyàn Léhì mú wá láti Jerúsálåmù níägbñta üdún kí á tó bí Krístì. Àwün wÿnyí ní “àwün ìwé márunti Mósè, . . . Àti pñlú ìwé ìrántí àwün Jû láti ìbñrñ, . . . títí déìbñrñ ìjüba Sädäkíàh, üba Júdà; Àti pñlú àwün ìsütålå àwün wòlîmímõ” (1 Nífáì 5:11–13). Ÿpÿlüpÿ ÿrÿ gågå bí a ti sü õ gan-anláti inú àwün àwo wÿnyí, tí ó nsü ÿrÿ Isaiah àtí àwün wòlî míràntí ó wà nínú bíbélì àti tí kò sí nínú bíbélì, ni ó yü nínú Ìwé tiMõmõnì.Ìwé ti Mõmõnì pín sí apá tàbí abala måädógún, tí a mÿ, yàtÿ sí

    ÿkan, gågå bí àwün ìwé, ti a n fi orúkü olórí äni tí o kÿwé nâ pè.Apá èkíní (àwün ìwé måfà tí ó ãâjú, títí de Ómúnì) jå ìyírÿpadà látiinú Àwün Àwo Kékeré ti Nífáì. Lârín àwün ìwé Ómúnì àti Mòsíàni àfisínú kan tí à npè ní Àwün Ÿrÿ Mõmõnì. Àfisínú yí so ìwé ìrántí a fín sórí Àwün Àwo Kékeré pÿ pñlú ìkékúrú Mõmõnì ti ÀwünÀwo Nlá.

    Abala tí ó gùn jùlü, láti Mòsíà dé Mõmõnì, pñlú orí keje,jå ìyírÿpadà ìkékúrú Mõmõnì ti Àwün àwo Nlá ti Nífáì. Abala tí aãe parí, láti Mõmõnì, orí kejü, dé òpin ìwé nâ, ni Mórónì, ümüMõmõnì fín, äni tí, låhìn tí ó ti parí ìwé ìrántí ìgbé ayé bàbá rñ, ãeìkékúrú ìwé ìrántí àwün ará Járådì (bí Ìwé ti Étérì) ó sì fi àwün apákan kún un tí a mÿ sí Ìwé ti Mórónì.

    Ní, tàbí níwÿn üdún 421 låhìn ikú Olúwa wa, Mórónì, tí ó jå

  • xiv

    ìkähìn nínú àwün wòlî-òpìtàn àwün ará Nífáì, fi èdídì di ìwé ìrántímímõ nâ ó sì pa á mõ sí Olúwa, kí á mú u jáde wá ní ìgbà ìkähìn, bíohùn Ülõrun ti sütålñ nípasñ àwün wòlî rñ àtijõ. Ní üdún 1823låhìn ikú Olúwa wa, Mórónì kannâ, tí ó ti jínde nígbànâ, bä WòlîJoseph Smith wò, ó sì gbé àwün àwo tí a fín fún un.

  • xv

    ORÚKÜ ÀTI ÄSÄ ÀWÜN ÌWÉ INU

    Ìwé ti Mõmõnì

    Orúkü Ojú Ewé

    Ìwé Kíni ti Nífáì . . . . . . . . . . . . . . . . . 1

    Ìwé Kejì ti Nífáì . . . . . . . . . . . . . . . . 47

    Ìwé ti Jákõbù . . . . . . . . . . . . . . . . . 104

    Ìwé ti Énõsì . . . . . . . . . . . . . . . . . 122

    Ìwé ti Járõmù . . . . . . . . . . . . . . . . . 124

    Ìwé ti Ómúnì . . . . . . . . . . . . . . . . . 125

    Àwün Ÿrÿ ti Mõmõnì . . . . . . . . . . . . . . 128

    Ìwé ti Mòsíà . . . . . . . . . . . . . . . . . 130

    Ìwé ti Álmà . . . . . . . . . . . . . . . . . 190

    Ìwé ti Hålámánì . . . . . . . . . . . . . . . . 356

    Nífáì Kåta . . . . . . . . . . . . . . . . . . 396

    Nífáì Kårin . . . . . . . . . . . . . . . . . 453

    Ìwé ti Mõmõnì . . . . . . . . . . . . . . . . 457

    Ìwé ti Étérì . . . . . . . . . . . . . . . . . 475

    Ìwé ti Mórónì . . . . . . . . . . . . . . . . 506

  • AMŸNÀ FÚN ÌWÉ MÍMÕ

    1. Jésù Krístì OlúwaÀwòrán láti üwõ Heinrich Hofmann

    2. Wòlî Joseph SmithÀwòrán láti üwõ Alvin GittinsWo “Ñrí Wòlî Joseph Smith,” ojú-ewé ix–xii

    3. Léhì ri LiahónàÀwòrán láti üwõ Arnold FribergWo 1 Nífáì 16, ojú-ewé 29–32

    4. Léhì àti àwün ènìyàn rä dé Ilñ ÌléríÀwòrán láti üwõ Arnold FribergWo 1 Nífáì 18, ojú-ewé 36–38

    5. Álmà rì awün eniyan bümi ninu Àwün Omi MõmõnìÀwòrán láti üwõ Arnold FribergWo Mòsíà 18, ojú-ewé 163–165

    6. Sámúålì ará Lámánì sü-tålñÀwòrán láti üwõ Arnold FribergWo Hålámánì 16, ojú-ewé 394–396

    7. Jésù Krístì bä Ilñ Amåríkà wòÀwòrán láti üwõ John ScottWo 3 Nífáì 11, ojú-ewé 418–420

    8. Mórónì bò ìwé ìrántí àwün ará Nífáì mõlñÀwòrán láti üwõ Tom LovellWo Mõmõnì 8, ojú-ewé 469–472

  • Ìwé Kíní ti Nífáì

    ÌJÜBA ÀTI IÃÅ ÌRÁNÃÅ RÑ

    Ìwé ìtàn nípa Léhì àti ìyàwó rñ Sáráíà, àti àwün ümükùnrin rñmårin, tí à n pè ní (bñrñ láti orí änítí ó dàgbà jù) Lámánì, Låmúålì,Sâmú, àti Nífáì. Olúwa kìlÿ fún Léhì láti kúrò ní ilñ Jerúsálåmù,nítorí tí ó sütålñ sí àwün ènìyàn nípa àìãedêdé wün wõn sì n wáÿnà láti run ìgbésí ayé rñ. Ó rin ìrìn-àjò üjõ måta sínú ijù pñlú ìdílérñ. Nífáì mú àwün arákùnrin rñ wõn sì padà sí ilñ Jerúsálåmù látigba ìwé ìrántí àwün Jû. Ìwé ìtàn ìjìyà wün. Wõn gbé àwün ümübìn-rin Íãmáålì ní aya. Wõn mú ìdílé wün wõn sì lü kúrò sínú ijù. Ìjìyààti ìpõnjú wün nínú ijù. Ipa ÿnà àwün ìrìn-àjò wün. Wõn dé ibi ominlá. Àwün arákùnrin Nífáì ãÿtñ sí i. Ó dâmú wün, ó sì kõ ükÿ. Wõnpe orúkü ibñ ní Ibi-Ÿpÿ. Wõn ré omi nlá nâ küjá sínú ilñ ìlérí, àtib∑b∑ lü. Èyí jå gågå bí ti ìwé ìtàn ti Nífáì; tàbí ní ÿnà míràn, èmi,Nífáì, ni ó kü ìwé ìrántí yî.

    ORI 1

    Nífáì bñrñ ìwé ìrántí àwün ènìyànrñ — Léhì ríran rí üwÿn iná kanó sì kà láti inú ìwé ìsütålñ kan —Ó yin Ülõrun, ó sü nípa bíbÿMessia nâ, ó sì sütålñ nípa ìparunJerúsálåmù — A ãe inúnibíni sí inípasñ àwün Jû. Ní ìwÿn üdún 600kí á tó bí Olúwa wa.

    ÈMI, Nífáì, nítorí tí a bími nípa àwün òbí dídára,nítorínâ a kõ mi nínú gbogboòye bàbá mi; àti nítorí pé mo tirí ÿpÿlüpÿ ìpõnjú ní ìgbà àwünüjõ mi, bíótilñríb∑, nítorí tímo ti rí ojúrere Olúwa lõpÿ nígbogbo àwün üjõ mi; b∑ni, nítorípé mo ti ní ìmÿ nla nípa ôreàti àwün ohun ìjìnlñ Ülõrun,nítorínâ mo ãe ìwé ìrántí àwünìãe mi ní àwün üjõ mi.

    2 B∑ni, mo ãe ìwé ìrántí ní èdèbàbá mi, èyí tí ó ní òye àwün Jûàti èdè àwün ará Égíptì.3 Mo sì mÿ wí pé ìwé ìrántí èyí

    tí mo ãe jå òtítõ; mo sì ãe é pñlúüwõ ara mi; mo sì ãe é gågåbí ìmÿ mi.

    4 Ó sì ãe ní ìbñrñ üdún kíníti ìjüba Sädäkíàh, üba Júdà,(bàbá mi, Léhì, tí ó ti gbé níJerúsálåmù ní gbogbo àwün üjõrñ) ; àt i ní üdún kan nâ yîÿpÿlüpÿ wòlî wá, wõn n sütålñ síàwün ènìyàn wí pé wün gbõdÿronúpìwàdà, bíb∑kõ ìlú nlá nìJerúsálåmù yíò di píparun.

    5 Nítorí-èyi ó sì ãe pé bàbá mi,Léhì, bí ó ãe jáde lü ó gbàdúràsí Olúwa, b∑ni, àní pñlú gbo-gbo ükàn rñ, fún ànfàní àwünènìyàn rñ.

    6 Ó sì ãe bí ó ãe n gbàdúrà síOlúwa, üwÿn iná kan wá ó sìwà lórí àpáta níwájú rñ; ó sì rí, ósì gbõ púpÿ; nítorí àwün ohuntí ó rí àti tí ó gbõ ó gbÿn ó sìwárìrì lõpÿlüpÿ.

    7 Ó sì ãe pé ó padà sí ilé tirñ níJerúsálåmù; ó sì ju ara rñ sí oríibùsùn rñ, nítorí tí a borî rñ pñlúÑmí àti àwün ohun èyí tí ó ti rí.

  • 1 Nífáì 1:8–20 2

    8 Nítorí tí a borí rñ báyî pñlúÑmí, a mú un lü nínú ìran, àní tíó fi rí àwün ÿrun tí ó ãí sílñ, ó sìwòye pé òun rí Ülõrun tí ó jókolórí ìtå-üba rñ, tí àjü àìníye àwünangålì si yî ka ní ìwà kíkürin àtiyíyin Ülõrun wün.9 Ó sì ãe pé ó rí Änìkan tí ó

    n sÿkalñ láti ârín ÿrun, ó sì ripé ìmõlñ rñ pÿ ju ti ôrùn níagbedeméjì üjõ.10 Ó sì tún rí àwün méjìlá kan

    tí wõn n tñlé e, tí dídán wün sìtayü ti ìràwÿ ní òfúrufú.11 Wõn sì sÿkalñ wõn sì lü kâ-

    kiri ní ojú-ilñ àgbáyé; äni ìãâjúsì wá ó sì dúró níwájú bàbá mi,ó sì fún un ní ìwé kan, ó sì fi àãäfún un pé kí ó kà á.12 Ó sì ãe pé bí ó ãe n kà á, ó

    kún fún Ñmí Olúwa.13 Ó sì kà á, wí pé: Ègbé,

    ègbé ni fún Jerúsálåmù, nítorímo ti rí àwün ohun ìríra rä!B∑ni, àti ÿpÿlüpÿ nkan sì ni bàbámi kà nípa Jerúsálåmù — pé a ópârun, àti àwün olùgbé inú rñ;ÿpÿ ni yíò ãègbé nípasñ idà,ÿpÿ sì ni a ó kó ní ìgbèkùn lü síBábílõnì.14 Ó sì ãe nígbà tí bàbá mi ti kà

    á tí ó sì ti rí ÿpÿlüpÿ ohun nláàti àwün ohun ìyanu, ó kígbeàwün ohun púpÿ sókè sí Olúwa;bíí: Títóbi àti ìyanu ni iãå rä,A! Olúwa Ülõrun Olódùmarè!Ìtå-üba rä ga ní òkè-ÿrun, b∑niagbára rä, àti ôre, àti ânú nbälórí gbogbo olùgbé ayé; àti,nítorí tí ìwü jå aláanú, ìwü kìyíò yπda àwün tí ó bá wá sõdÿrä pé kí wõn ó ãègbé!15 Bí irú eleyî sì ni èdè bàbá mi

    ní yínyin Ülõrun rñ; nítorí ükànrñ yÿ, gbogbo ükàn rñ sì kún,

    nítorí àwün ohun èyí tí ó ti rí,b∑ni, èyí tí Ülõrun ti fihàn án.

    16 Àti nísisìyí èmi, Nífáì, kò sìãe ñkúnrårå ìwé ìtàn àwün ohunèyí tí bàbá mi ti kü, nítorí tí óti kü ÿpÿlüpÿ ohun èyí tí ó rínínú àwün ìran àti àlá; ó sì tikü ÿpÿlüpÿ ohun pñlú, èyí tí ósütålñ tí ó sì sü fún àwün ümürñ, nípa èyí tí èmi kò ní ãe ñkún-rårå ìwé ìtàn.

    17 Ãùgbõn èmi yíò ãe ìwéìtàn àwün ìãe mi ní àwün üjπmi. Kíyèsî, mo ãe ìkékúrú ìwéìrántí bàbá mi, sórí awün àwoèyí tí mo ti ãe pñlú üwõ ara mi;nítorí-èyi, låhìn tí mo bá ti kéìwé ìrántí bàbá mi kúrú nígbànâ ni èmi yíò ãe ìwé ìtàn ti ìgbésíayé tèmi.

    18 Nítorínâ, mo få kí ñyin mÿ,pé låhìn tí Olúwa ti fi ÿpÿlüpÿohun ìyanu han sí bàbá mi, Léhì,b∑ni, nípa ìparun Jerúsálåmù,kíyèsî ó jáde lü sí ârín àwünènìyàn nì, ó sì bñrñ sí sütålñ ó sìn kéde sí wün nípa àwün ohunèyí tí ó ti rí àti tí ó ti gbõ.

    19 Ó sì ãe tí àwün Jû fi ãe älåyànítorí àwün ohun èyí tí ó jårî sínípa wün; nítorí tí ó jårî nítôtõsí ìwà búburú wün àti àwünohun ìríra wün; ó sì jårî pé àwünohun èyí tí òun rí tí òun sì gbõ,àti pñlú àwün ohun èyí tí òun kànínú ìwé nâ, fi hàn kedere bíbÿMessia kan, àti pñlú ìràpadà ayé.

    20 Nígbà tí àwün Jû sì gbõàwün nkan wÿnyí wõn bínú síi; b∑ni, àní, bî sí àwün wòlî ìgbààtijõ, tí wõn ti sü sóde, tí wõn sìsü ní òkúta, tí wõn sì pa; wõn sìtún wá ñmi rñ, kí wõn lè mú unkúrò. Ãùgbõn kíyèsí i, èmi, Nífáì,yíò fihàn sí yín pé ânú Olúwa tí

  • 3 1 Nífáì 2:1–13

    ó ní ìtùnú nbä lórí gbogbo àwünäni tí ó ti yàn, nítorí ti ìgbàgbõwün, láti ãe wõn ní alágbára ànísí agbára ìdásílñ.

    ORI 2

    Léhì mú ìdílé rñ lü sínú ijù låbâÒkun Pupa—Wõn fi ohun ìní wünsílñ — Léhì rúbü sí Olúwa ó sì kõàwün ümükùnrin rñ láti pa àwünòfin mõ — Lámánì àti Låmúålì kùnsí bàbá wün — Nífáì ãe ígbüràn ósì gbàdúrà ní ìgbàgbõ; Olúwa bâsÿrÿ, a sì yàn án láti jüba lórí àwünarákùnrin rñ. Ní ìwÿn üdún 600 kíá tó bí Olúwa wa.

    Nítorí kíyèsî i, ó sì ãe tí Olúwabá bàbá mi sÿrÿ, b∑ni, àní nínúàlá, ó sì sü fún un: Alábùkún fúnni ìwü Léhì, nítorí àwün ohunèyí tí ìwü ti ãe; àti nítorí ìwü ti jåolóotõ tí ìwü sì ti kéde sí àwünènìyàn wÿnyí, àwün ohun èyítí mo pàãä fún ü, kíyèsî i, wõnn wá láti mú ñmí rä kúrò.2 Ó sì ãe tí Olúwa pàãä fún

    bàbá mi, àní nínú àlá, pé kí ó múìdílé rñ kí ó sì lü kúrò sínú ijù.3 Ó sì ãe tí ó ãe ígbüràn sí ÿrÿ

    Olúwa, nítorí-èyi, ó ãe gågå bíOlúwa ãe pàãä fún un.4 Ó sì ãe tí ó lü kúrò sínú ijù. Ó

    sì fi ilé rñ sílñ, àti ilñ ìní rñ, àtiwúrà rñ, àti fàdákà rñ, àti àwünohun oníyebíye rñ, kò sì múohunkóhun pñlú rñ, àfi ìdílé rñ,àti àwün èsè, àti àwün àgõ, ó sìlü kúrò sínú ijù.5 Ó sì wá sísàlñ ní ñbá itòsí

    èbúté Òkun Pupa; ó sì rinìrìn-àjo nínú ijù ní ñbá èyí tí ówà nítòsí Òkun Pupa; ó sì rinìrìn-àjò nínú ijù pñlú ìdílé rñ,

    èyí tí i ãe ìyá mi, Sáráíà, àtiàwün ñgbõn mi ükùnrin, tí wõnjå Lámánì, Låmúålì, àti Sâmú.

    6 Ó sì ãe pé nígbà tí ó ti rinìrìn-àjò üjõ måta nínú ijù, ó täàgõ rñ sí àfonífojì låbâ ñgbå odòomi kan.

    7 Ó sì ãe tí ó kõ päpä òkútakan, ó sì ãe ürä kan sí Olúwa, ósì fi üpå fún Olúwa Ülõrun wa.

    8 Ó sì ãe tí ó pe orúkü odò nâní, Lámánì, ó sì n ãàn sínú ÒkunPupa; àfonífojì nâ sì wà ní ñbáitòsí änu rñ.

    9 Àti nígbàtí bàbá mi sì rí i wípé omi odò nâ nãàn sínú ìsunÒkun Pupa, ó wí fún Lámánì,wí pé: À! ìwü ìbá lè dàbí odò yî,tí ó nãan títí sínú orísun gbogboìwà òdodo!

    10 Ó sì tún wí fún Låmúålì: À!ìwü ìbá lè dàbí àfonífojì yî, tí ówà gbün-in tí ó sì dúróãinãin, tíkò sì lè mì ní pípa àwün òfinOlúwa mõ!

    11 Nísisìyí èyí ni ó wí nítorí tiürùn líle Lámánì àti Låmúålì;nítorí kíyèsî i wõn n kùn sínúní ÿpÿlüpÿ ohun sí bàbá wün,nítorí tí ó jå aríran ükùnrin, ó sìti tõ wün jáde ní ilñ Jerúsálåmù,láti kúrò ní ilñ ìní wün, àti wúràwün, àti fàdákà wün, àti àwünnkan oníyebíye wün, láti ãègbénínú ijù. Èyí sì ni wõn sü wípé ó ti ãe nítorí ti ìrò aláìgbõnükàn rñ.

    1 2 B á y î s ì n i L á m á n ì à t iLåmúålì, tí wõn jå agba, kùn sìbàbá wün. Wõn sì kùn nítorí tíwün kò mõ ìbálò Ülõrun nì, änití ó dá wün.

    13 B∑ni wün kò gbàgbõ wí péJerúsálåmù, ìlú nla nì, lè parungågå bí ÿrÿ àwün wòlî. Wõn

  • 1 Nífáì 2:14–3:4 4

    sì dàbí àwün Jû tí ó wà níJerúsálåmù, tí wõn n wá látimú ñmí bàbá mi kúrò.14 Ó sì ãe tí bàbá mi bá wün

    sÿrÿ ní àfonífojì Låmúålì, pñlúagbára, nítorí tí ó kún fún Ñmí,títí di ìgbà tí ara wõn fi gbÿnníwájú rñ. Ó sì dâmú wün, tí wünkò fi lè sÿrÿ lòdì sí i; nítorí-èyi,wõn ãe bí ó ãe pàãä fún wün.15 Bàbá mi sì gbé nínú àgõ kan.16 Ó sì ãe tí èmi, Nífáì, nítorí

    tí mo jä ümüdé lõpÿlüpÿ, bíóti-lñríb∑ tí mo tóbi ní ìnà sókè ènì-yàn, àti pñlú nítorí tí mo níìfå nlá láti mÿ nípa àwün ohunìjìnlñ Ülõrun, nítorí-èyi, mo kí-gbe pe Olúwa; sì kíyèsî i ó sì bñmí wò, ó sì mú ükàn mi rÿtí mo fi gba gbogbo àwün ÿrÿnâ gbõ, èyí tí bàbá mi ti sü;nítorí-èyi, èmi kò ãÿtñ sí i gågåbí àwün arákùnrin mi.17 Mo sì bá Sâmú sÿrÿ, mo

    jå kí ó mÿ nípa àwün ohun tíOlúwa ti fihàn sí mi nípasñ ÑmíMímõ rñ. Ó sì ãe tí ó gba àwünÿrÿ mi gbõ.18 Ãùgbõn, kíyèsî i, Lámánì àti

    Låmúålì kò få fetísílñ sí awünÿrÿ mi; nítorí tí inú mi sì bàjånítorí líle ükàn wün mo kígbepe Olúwa fún wün.19 Ó sì ãe tí Olúwa wí fún

    mi, wí pé: Alábùkún-fún ni ìwü,Nífáì, nítorí ìgbàgbõ rä, nítoríìwü ti wá mi låsÿläsÿ, pñlú ìrñlñükàn.20 Níwÿn bí ìwü bá sì n pa

    àwün òfin mi mõ, ìwü yíò ãerere, a ó sì ãe amÿnà rä lü sí ilñìlérí kan; b∑ni, àní ilñ èyí tí moti pèsè fún ü; b∑ni, ilñ èyí tíó jå àãàyàn ju gbogbo àwünilñ míràn.

    21 Níwÿn bí àwün arákùnrinrä bá sì n ãÿtñ sí ü, a ó gé wünkúrò níwájú Olúwa.

    22 Níwÿn bí ìwü bá sì n paàwün òfin mi mõ, a ó fi õ ãealákòso àti olùkõ lórí àwünarákùnrin rä.

    23 Nítorí kíyèsî i, ní üjõ nâ tíwõn bá ãÿtñ sí mi, èmi yíò fiwõn bú àní pñlú ìfibú kíkan,nwün kì yíò sì ní agbára lóríirú-ümü rä àfi tí wõn ó bá ãÿtñ síèmi nâ pñlú.

    24 Bí ó bá sì ãe pé wõn ãÿtñ sími , wün yíò jå pàãán fúnirú-ümü rä, láti rú wün sókè níàwün ÿnà ìrantí.

    ORI 3

    Àwün ümükùnrin Léhì padà síJerúsálåmù láti gba àwün àwoidä—Lábánì kÿ láti fi àwün àwo nâsílñ — Nífáì gba àwün arákùnrinrñ níyànjú ó sì mú wün lõkàn le —Lábánì j í ohun ìní wün ó sìgbìdánwò láti pa wõn—Lámánì àtiLåmúålì lu Nífáì àti Sâmú, angålìkan sì bá wün wí. Ní ìwÿn üdún600 sí 592 kí á tó bí Olúwa wa.

    Ó sì ãe tí èmi, Nífáì, padà látis ísÿrÿ pñlú Olúwa, sí àgõbàbá mi.

    2 Ó sì ãe tí ó wí fún mi, wí pé:Kíyèsî i mo ti lá àlá kan, nínúèyí tí Olúwa ti pàãä fún mi péìwü àti àwün arákùnrin rä yíòpadà sí Jerúsálåmù.

    3 Nítorí kíyèsî i, Lábánì ní ìwéìrántí àwün Jû àti pñlú ìtàn ìdíléàwün baba-nlá mi, a sì fín wünsórí àwün àwo idä.

    4 Nítorí-èyi, Olúwa ti pàãä fúnmi pé kí ìwü àti àwün arákùnrin

  • 5 1 Nífáì 3:5–21

    rä lü sí ilé Lábánì, kí ä sì wáàwün ìwé ìrántí nâ, kí ä sì múwün wá sísàlñ níhin sínú ijù.5 Àti nísisìyí, kíyèsî i àwün

    arákùnrin rä n kùn, wõn n wípé ohun tí ó le ni èyí tí mo bèrèlõwõ wün; ãùgbõn kíyèsî i èmikò bèrè rñ lõwõ wün, ãùgbõn ójå àãä Olúwa.6 Nítorínâ lü, ümü mi, ìwü yíò

    sì rí ojú rere lõdÿ Olúwa, nítorítí ìwü kò kùn.7 Ó sì ãe tí èmi, Nífáì, sü fún

    bàbá mi: Èmi yíò lü láti ãeàwün ohun tí Olúwa ti pa láãä,nítorí tí èmi mÿ wí pé Olúwakì yíò pa àãä fún àwün ümüènìyàn, bíkòãe pé òun yíò pèsèÿnà fún wün pé kí wõn lèparí ohun nâ èyí tí òun pa láãäfún wün.8 Ó sì ãe nígbà tí bàbá mi ti gbõ

    àwün ÿrÿ wÿnyí ó yÿ lõpÿlüpÿ,nítorí ó mÿ wí pé mo ti jå alábù-kún-fún lõdÿ Olúwa.

    9 Èmi, Nífáì, àti àwün arákùnrinmi sì mú ìrìn-àjò wa ní ijù, pñlúàwün àgõ wa, láti gòkè lü síilñ Jerúsálåmù.10 Ó sì ãe nígbà tí a ti gòkè lü sí

    ilñ Jerúsálåmù, èmi àti àwünarákùnrin mi fi ÿrÿ lü ara wa.11 A sì ãå kèké — tani nínú wa

    ni kí ó lü sí ilé Lábánì. Ó sì ãe tíkèké mú Lámánì; Lámánì sì wüinú ilé Lábánì lü ó sì sÿrÿ pñlúrñ bí ó ãe jóko ní ilé rñ.12 Ó sì bêrè lõwõ Lábánì àwün

    ìwé-ìrántí èyí tí a gbå sórí àwünàwo idä, èyí tí ó ní ìtàn ìdílébàbá mi nínú.

    13 Sì kíyèsî i, ó sì ãe tí Lábánìbínú, ó sì tì í jáde kúrò ní ÿdÿrñ; kì yíò sì jå kí ó gba àwünìwé-ìrántí nâ. Nítoríti, ó sü fún

    un: Kíyèsî i ìwü jå ülõãà, èmiyíò sì pa õ.

    14 Ãùgbõn Lámánì sá kúrò níÿdÿ rñ, ó sì sü àwün ohun tíLábánì ti ãe, fún wa. A sì bñrñ síkún fún ìbànújå lõpÿlüpÿ, àwünarákùnrin mi sì få padà sí ÿdÿbàbá mi nínú ijù.

    15 Ãùgbõn kíyèsî i mo sü fúnwün pé: Bí Olúwa ti mbä, àti bíàwa ti mbä, àwa kì yíò sÿkalñ lüsí ÿdÿ bàbá wa nínú ijù títí àwaó fi ãe ohun tí Olúwa ti pàãä fúnwa parí.

    16 Nítorí-èyi, ä jå kí á ãe òtítõní pípa àwün òfin Olúwa mõ;nítorínâ ä jå kí á sÿkalñ lü sí ilñìní bàbá wa, nítorí ä kíyèsî i ó fiwúrà àti fàdákà sílñ, àti oríãiríãiürÿ. Gbogbo eleyî ni ó sì ãe nítoríàwün òfin Olúwa.

    17 Nítorí ó mÿ pé Jerúsálåmùyíò di píparun, nítorí ti ìwàbúburú àwün ènìyàn nâ.

    18 Nítorí kíyèsî i, wõn ti kü ÿrÿàwün wòlî sílñ. Nítorí-èyi bíbàbá mi bá gbé ní ilñ nâ lñhìn tía ti pàãä fún un láti sá jáde kúròní ilñ nâ, kíyèsî i, òun yíò ãègbépñlú. Nítorí-èyi, ó di dandan fúnun láti sá jáde kúrò ní ilå nâ.

    19 Sì kíyèsî i, ó jå ügbõn nínúÜlõrun pé kí àwa gba àwünìwé-ìrántí wÿnyí, kí á lè ãe ìtõjúèdè àwün bàbá wa fún àwünümü wa;

    20 Àti pñlú kí àwa lè ãe ìtõjúfún wün, àwün ÿrÿ èyí tí a tisü láti änu gbogbo àwün wòlîmímõ, èyí tí a ti fi fún wünnípasñ Ñmí àti agbára Ülõrun,láti ìgbà tí ayé ti bñrñ, àní títí diàkókò lõwõlõwõ yî.

    21 Ó sì ãe pé irú èdè báyî ni mofi yí àwün arákùnrin mi lõkàn

  • 1 Nífáì 3:22–4:3 6

    padà, kí wõn lè ãe òtítõ ní pípaàwün òfin Ülõrun mõ.22 Ó sì ãe tí a sÿkalñ lü sí ilñ ìní

    wa, a sì ãa wúrà wa jü; àti fàdákàwa, àti àwün nkan oníyebíye wa.23 Låhìn tí a sì ti ãa àwün nkan

    wÿnyí jü, a lü sókè l∑kejì sí iléLábánì.24 Ó sì ãe tí a wülé tü Lábánì

    lü, a sì bêrè lõwõ rñ pé kí ó fúnwa ní àwün ìwé-ìrántí nâ èyí tía fín sórí àwün àwo ìdä, fún èyítí àwa yíò fún un ní wúrà wa,àti fàdákà wa, àti gbogbo àwünnkan oníyebíye wa.25 Ó sì ãe nígbà tí Lábánì rí

    ohun ìní wa, àti wí pé ó pÿlõpÿlüpÿ, ó ãe ìfåkúf∑ sí i, tób∑tí ó tì wá sóde, ó sì rán àwünìránãå rñ láti pa wá, kí ó lè gbaohun ìní wa.26 Ó sì ãe tí a sá fún àwün

    ìránãå Lábánì, tí ó fi jå wí pé aní láti fi ohun ìní wa sílñ, ó sì bõsí üwõ Lábánì.27 Ó sì ãe tí a sá sínú ijù,

    àwün ìránãå Lábánì kò sì bá wa,a sì fi ara wa pamõ nínú ihòàpáta kan.

    28 Ó sì ãe tí Lámánì bínú sí mi,àti pñlú sí bàbá mi; bákan nâ sìni Låmúålì, nítorí ó fetísílñ síÿrÿ Lámánì. Nítorí-èyi Lámánìàti Låmúålì sü ÿpÿlüpÿ ÿrÿ lílesí wa, àwa àbúrò wün ükùnrin,wõn sì lù wá àní pñlú ÿpá.29 Ó sì ãe bí wõn ãe n lù wá

    pñlú ÿpá, kíyèsî i, angålì Olúwakan wá ó sì dúró níwájú wün, ósì wí fún wün, wí pé: Èéãe tí ñyinfi n lu àbúrò yín ükùnrin pñlúÿpá? Ñyin kò ha mÿ pé Olúwati yàn án láti jå alákôso lórí yín,ó sì ãe èyi nítorí àìãedêdé yín?Kíyèsî i ñyin yíò tún gòkè lü

    sí Jerúsálåmù, Olúwa yíò sì fiLábánì lée yín lõwõ.

    30 Låhìn tí ángålì nâ sì ti sÿrÿsí wa, ó lü kúrò.

    31 Låhìn tí ángålì nâ sì ti lükúrò, Lámánì àti Låmúålì túnbñrñ sí kùn, wí pé: Báwo ni yíò tiãe é ãe pé Olúwa yíò fi Lábánì léwa lõwõ? Kíyèsî i ó jå alágbáraükùnrin, ó sì lè pàãä fún âdõta,b∑ni, àní ó lè pa âdõta; njå êãe tíkò ní le pa wá?

    ORI 4

    Nífáì pa Lábánì gågå bí àãä Olúwaó sì gba àwün àwo idä nâ nípalílo àrékérekè — Sórámù yàn látidarapÿ mõ ìdílé Léhì nínú ijù. Níìwÿn üdún 600 sí 592 kí á tó bíOlúwa wa.

    Ó sì ãe tí mo wí fún àwünarákùnrin mi, wí pé: Ä jå kí á túngòkè lü sí Jerúsálåmù, ä sì jå kí áãe òtítõ ní pípa àwün òfin Olúwamõ; nítorí ä kíyèsî i ó lágbára jugbogbo ayé, njå êãe tí kò leèlágbára ju Lábánì àti âdõta rñ,b∑ni, tàbí ju ägbêgbñrún rñ pâpâ?

    2 Nítorínâ ä jå kí á gòkè lü; ä jåkí á ní ágbára tí ó dàbí ti Mósè;nítorí ó sÿrÿ nítôtõ sí omi ÒkunPupa wõn sì pínyà síhin àtisõhun, àwün bàbá wa sì lâ já,jáde ìgbèkun, lórí ìyàngbä ilñ,àwün ägbå ümü ogun Fáráò sìtñlé wün wõn sì rì sínú omiÒkun Pupa.

    3 Wàyí ä kíyèsî i ñyin mÿ wí péèyí jå òtítõ; ñyin sì mÿ pñlú wípé angålì kan ti sÿrÿ sí yín; ê hati se tí ñyin yíò tún siyèméjì? Äjå kí á gòkè lü; Olúwa lè gbàwá, gågå bí àwün bàbá wa, kí ó

  • 7 1 Nífáì 4:4–22

    sì pa Lábánì run, gågå bí àwünará Égíptì.4 Nísisìyí nígbàtí mo ti sü

    àwün ÿrÿ wÿnyí, wõn ãì n bínúsíbñ, wõn sì múra si láti kùn;bíótilñríb∑ wõn tñlé mi gòkè títía fi dé ñhìn odi Jerúsálåmù.5 Ó sì jå ní òru; mo sì mú kí

    wõn fi ara wün pamõ såhìn odi.Låhìn tí wõn sì ti fi ara wünpamõ, èmi, Nífáì, pa-kõlõ sínú ìlúnlá nâ mo sì lü níhà ilé Lábánì.6 Ñmi sì n tõ mi, n kò mÿ tålñ

    àwün ohun èyí tí èmi ìbá ãe.7 Bíótilñríb∑ mo tñ síwájú, bí

    mo sì ti súnmõ ilé Lábánì mo ríükùnrin kan, ó sì ti ãubú sí ilñníwájú mi, nítorí tí ó ti muàmupara pñlú ütí-wáínì.

    8 Nígbà tí mo sì súnmõ ÿdÿ rñmo ri wí pé Lábánì ni.9 Mo sì ãàkíyèsí idà rñ, mo sì

    fà á jáde kúrò nínú àkÿ rñ;êkù rñ jå ti wúrà tí ó dá ãáká,iãå rñ sì dára lõpÿlüpÿ, mo sìri wí pé ojú idà rñ jå ti irin oní-yebíye jùlü.10 Ó sì ãe Ñmí rÿ mí láti

    pa Lábánì; ãùgbõn mo sü nínúükàn mi: N kò ta ñjñ ènìyàn sílñnígbà-kûgbà rí. Mo sì súnrakìmo få wí pé kí n máãe pa á.11 Ñmí sì tún sü fún mi: Kíyèsî

    i Olúwa ti jÿwõ rñ lé ü lõwõ.B∑ni, mo sì tún mÿ wí pé ó ti wáÿnà láti gba ñmí tèmi; b∑ni, òunkò sì fetí sí àwün òfin Olúwa; ósì ti gba ohun ìní wa lü pñlú.12 Ó sì ãe tí Ñmí tún sü fún mi:

    Pa á, nítorí Olúwa ti jÿwõ rñlé ü lõwõ;13 Kíyèsî i Olúwa yíò pa

    ènìyàn búburú láti lè mú àwünèrò rere rñ jáde wá. Ó sàn kíènìyàn kan ãègbé ju kí orílñ-èdè

    kan rñhìn nínú ìgbàgbõ kí wõnsì ãègbé.

    14 Àti nísisìyí, nígbàtí èmi,Nífáì, ti gbõ àwün ÿrÿ wÿnyí,mo rántí àwün ÿrÿ Olúwa èyítí o wí fún mi nínú ijù, wí pé:Níwÿn bí àwün irú-ümü rä bápa àwün òfin mi mõ, wün yíò ãerere ní ilñ ìlérí nâ.

    15 B∑ni, mo sì rò ó pñlú wí péwün kò le è pa àwün òfin Olúwamõ gågå bí òfin Mósè, bí kò ãepé wõn bá ní òfin nâ.

    16 Mo sì mÿ pñlú wí pé a fínòfin nâ sórí àwün àwo idä nâ.

    17 Ñwñ, mo mÿ wí pé Olúwa tijÿwõ Lábánì lé mi lõwõ fún ìdíèyí — kí èmi lè gba àwün ìwéìrántí nâ gågå bí àwün òfin rñ.

    18 Nítorínâ mo gba ohùn Ñmígbõ, mo sì mú Lábánì níbi irunorí, mo sì gé orí rñ kúrò pñlúidà òun tìkara rñ.

    19 Låhìn tí mo sì ti gé orí rñkúrò pñlú idà tirñ, mo mú awünñwù Lábánì mo sì wÿ wõn síara tèmi; b∑ni, àní kan èyí tí ókéré jùlü; mo sì gbé ìhámõra rñwÿ sí ñgbå mi.

    20 Låhìn tí mo sì ti ãe èyí, mojáde lü sí ibi àpótí ìãura Lábánì.Bí mo sì ti n jáde lü síhà ibiàpótí ìãura Lábánì, kíyèsî i, morí ìránãå Lábánì äni tí ó ní kõkõ-rõ ibi àpótí ìãura nâ lõwõ. Mosì pàãä fún un ní ohùn Lábánì,pé kí ó lü pñlú mi sínú ibiàpótí ìãura.

    21 Ó sì ãèbí ÿgá òun, Lábánì,ni mí, nítorí ó rí awün ñwù àtiidà tí mo sán mõ ñgbå mi pñlú.

    22 Ó sì bá mi sÿrÿ nípa àwünàgbàgbà àwün Jû, ó mÿ wí péÿgá òun, Lábánì, ti jáde ní òrupñlú wün.

  • 1 Nífáì 4:23–38 8

    23 Mo sì bá a sÿrÿ bí äni péLábánì ni.24 Mo sì tún wí fún un wí pé

    èmi yíò gbé àwün ìfín, èyí tí ówà lórí àwün àwo idä, lü fúnàwün ñgbõn mi ükùnrin, tí wõnwà låhìn odi.25 Mo sì tun pàãä fún un wí pé

    kí ó tñlé mi.26 Òun nâ, nítorí tí ó rò wí pé

    mo n sÿrÿ nípa àwün arákùnrinìjü onígbàgbõ, àti wí pé nítôtõni mo jå Lábánì nì, äni tí mo tipa, nítorí-èyi ó tñlé mi.27 Ó sì bá mi sÿrÿ lõpÿlüpÿ

    ìgbà nípa àwün àgbàgbà àwünJû, bí mo ãe n jáde lü sí ÿdÿàwün arákùnrin mi, tí wõn wàlåhìn odi.28 Ó sì ãe nígbà tí Lámánì rí mi

    ó bñrù lõpÿlüpÿ, b∑ nâ gågå sìni Låmúålì àti Sâmú. Wõn sì sákúrò níwájú mi; nítorí wõn ãèbíLábánì ni, àti wí pé ó ti pamí ó sì ti wá láti mú ñmí wünkúrò pñlú.29 Ó sì ãe tí mo ké sí wün, wõn

    sì gbõ mi; nítorí-èyi wõn dåkunsísá kúrò lõdÿ mi.30 Ó sì ãe nígbà tí ìránãå

    Lábánì rí àwün arákùnrin mi óbñrñ sí n gbÿn, ó sì ti få sá kúròníwájú mi kí ó sì padà sí ìlú nláJerúsálåmù.31 Àti nísisìyí èmi, Nífáì, níto-

    rítí mo jå ènìyàn tí ó tóbi ní ìnàsókè ènìyàn, àti pñlú nítorítí moti gba agbára púpÿ lõwõ Olúwa,nítorínâ mo gbá ìránãå Lábánìmú, mo sì dì í mú, kí ó má bá sá.32 Ó sì ãe tí mo bá a sÿrÿ, wí

    pé tí ó bá lè fetí sí ÿrÿ mi, bíOlúwa ti wà, tí èmi sì wà, àníb∑ni bí òun bá fetí sí ÿrÿ wa,àwa yíò yπda ñmí rñ.

    33 Mo sì wí fún un, àní pñlúìbúra, wí pé kí ó máãe bñrù;wí pé yíò di òmìnira bí àwaãe wà bí òun bá sÿkalñ sínú ijùpñlú wa.

    34 Mo sì tún sü fún un, wí pé:Dájúdájú Olúwa ti pá láãä fúnwa láti ãe ohun yî; njå àwa kìyíò sì ha ãe âpün ní pípa àwünòfin Olúwa mõ? Nítorínâ, bí ìwübá lè sÿkalñ sínú ijù sõdÿ bàbámi ìwü yíò ní àyè pñlú wa.

    35 Ó sì ãe ti Sórámù sì ní ìgbo-yà nítorí àwün ÿrÿ èyí tí mo sü.Nísisìyí Sórámù ni orúkü ìránãånâ; ó sì ãe ìlérí wí pé òun yíòsÿkalñ sínú ijù sí ÿdÿ bàbá wa.B∑ni, ó sì ãe ìbúra fún wa wí péòun yíò dúró-låhìn pñlú wa látiìgbà nâ lü.

    36 Nísisìyí àwa få kí ó dúró-låhìn pñlú wa fún ìdí èyí, kíàwün Jû má bá mÿ nípa sísákúrò wa sínú ijù, kí wõn má bálépa wa kí wõn sì run wá.

    37 Ó sì ãe nígbà tí Sórámù tiãe ìbúra fún wa, ìbñrùbojo wadåkun nípa rñ.

    38 Ó sì ãe tí a mú àwün àwoidä nâ àti ìránãå Lábánì, a sì lükúrò sínu ijù, a sì rin ìrìn-àjò síàgõ bàbá wa.

    ORI 5

    Sáráíà ráhùn sí Léhì—Àwün méjêjìyÿ lórí ìpadàbÿ àwün ümükùnrinwün — Wõn rú äbü — Àwün àwoidä nâ ní àküsílñ ti Mósè àti àwünwòlî nínú—Àwün àwo nâ fihàn péLéhì jå àtñlé Jósåfù — Léhì sütålñnípa irú-ümü rñ àti nípa ìpamõàwün àwo nâ. Ní ìwÿn üdún 600 sí592 kí á tó bí Olúwa wa.

  • 9 1 Nífáì 5:1–16

    Ó sì ãe låhìn tí a ti sÿkalñ sínúijù sí ÿdÿ bàbá mi, kíyèsî i, ókún fún ayÿ, àti ìyá mi, Sáráíàpñlú, yÿ lõpÿlüpÿ, nítorí nítôtõó ti ãÿfÿ nítorí wa.2 Nítorí ó ti ãèbí a ti ãègbé

    nínú ijù; ó sì tún ti ráhùn sí bàbámi, tó sü fún un wí pé a-ríranükùnrin ni; ó wí pé: Kíyèsî iìwü ti tõ wa kúrò nínú ilñ ìní wa,àwün ümükùnrin mi kò sì sí mõ,a sì ãègbé nínú ijù.3 Irú èdè báyî sì ni ìyá mi ti fi

    ráhùn sí bàbá mi.4 Ó sì ti ãe tí bàbá mi sü fún

    un, wí pé: Mo mÿ wí pé mo jåaríran ükùnrin; nítorí bí kòbá ãe pé èmi ti rí àwün ohunÜlõrun nínú ìran èmi ìbá mámõ ôre Ülõrun, ãùgbõn èmi ìbáti dúró-låhìn ní Jerúsálåmù,èmi ìbá sì ti ãègbé pñlú àwünarákùnrin mi.5 Ãùgbõn kíyèsî i, èmi ti gba

    ilñ ìlérí, nínú àwün ohun èyítí mo n yÿ; b∑ni, èmi sì mÿ wípé Olúwa yíò gba àwün ümü-kùnrin mi kúrò ní üwõ Lábánì,yíò sì tún mú wün sÿkalñ sí ÿdÿwa nínú ijù.6 Irú èdè báyî sì ni bàbá mi,

    Léhì, fi tu ìyá mi, Sáráíà, nínúnípa wa, ní àkókò tí a rinìrìn-àjò nínú ijù sókè lü sí ilñJerúsálåmù, láti gba ìwé ìrántíàwün Jû.7 Nígbà tí a sì ti padà sí àgõ

    bàbá mi, kíyèsî i ayÿ wün kún,a sì tu ìyá mi nínú.8 Ó sì sÿrÿ, wí pé: Nísisìyí mo

    mÿ ní ìdánilójú wí pé Olúwati pá láãä fún ükü mi láti sá síinú ijù; b∑ni, mo sì tún mÿ níìdánilójú wí pé Olúwa ti dâbòbò àwün ümükùnrin mi, ó sì

    gbà wõn kúrò ní üwõ Lábánì,ó sì ti fún wün ní agbára nípaèyí tí wõn lè fi parí ohun tíOlúwa ti pàãä fún wün. Irú èdèbáyî ni ó sì sü.

    9 Ó sì ãe tí wõn sì yÿ lõpÿlüpÿ,wõn sì rú äbü àti äbü-ürä sísunsí Olúwa; wõn sì fi üpå fúnÜlõrun Isráålì.

    10 Låhìn tí wõn sì ti fi üpå fúnÜlõrun Isráålì, bàbá mi, Léhì,gba àwün ìwé ìrántí nâ èyí tí afín sórí àwün àwo idä, ó sì yñwõn wò láti ìbñrñ.

    11 Ó sì ãe àkíyèsí wí pé wõn níàwün ìwé márun ti Mósè nínú,èyí tí ó pèsè ìwé ìtàn ñdá ayé àtipñlú ti Ádámù àti Éfà, àwün tíwõn jå òbí wa èkíní;

    12 Àti pñlú ìwé ìrántí àwün Jûláti àtètèkõãe, àní títí di ìbñrñìjüba Sädäkíàh, üba Júdà;

    13 Àti pñlú àwün ìsütålñ àwünwòlî mímõ, láti àtètèkõãe, ànítítí di ìbñrñ ìjüba Sädäkíàh; àtipñlú ÿpÿlüpÿ ìsütålñ èyí tí a tisü láti änu Jeremíàh.

    14 Ó sì ãe pé bàbá mi, Léhì,tún rí ìtàn ìdílé àwün bàbá rñlórí àwün àwo idä nâ; nítorí-èyió mÿ wí pé òun jå àtñlé Jósåfù;b∑ ni, àní Jósåfù nì, äni tí ójå ümü Jákõbù, äni tí a tà síÉgíptì, äni tí a sì pamõ nípaüwõ Olúwa, kí ó lè ãe ìpamõbàbá rñ, Jákõbù, àti gbogboagbolé rñ kúrò nínú ãíãègbépñlú ìyàn.

    15 A sì tõ wün kúrò ní ìgbèkunàti kúrò ní ilñ Égíptì, nípaüwõ Ülõrun kan nâ äni tí ó ti pawõn mõ.

    16 Báyî sì ni bàbá mi, Léhì, ãemÿ nípa ìtàn ìdílé àwün bàbá rñ.Lábánì sì jå àtñlé Jósåfù pñlú,

  • 1 Nífáì 5:17–6:6 10

    nítorínâ ni òun àti àwün bàbárñ ãe tõjú àwün ìwé ìrántí nâ.17 Àti nísisìyí nígbà tí bàbá mi

    rí gbogbo àwün nkan wÿnyí, ókún fún Ñmí, ó sì bñrñ sí sütålñnípa irú-ümü rñ —18 Wí pé àwün àwo idä wÿnyí

    yíò jáde lü sí gbogbo orílñ-èdè,ìbátan, èdè, àti ènìyàn tí ó jå tiirú-ümü rñ.

    19 Nítorí-èyi, ó sü wí pé àwünàwo idä wÿnyí kì yíò ãègbéláé; b∑ni wün kì yíò farasinní ÿnàkünà nípasñ àkókò. Ósì sütålñ ÿpÿlüpÿ ohun nípairú-ümü rñ.

    20 Ó sì ãe tí títí di báyî èmi àtibàbá mi ti pa àwün òfin nâ mõèyí tí Olúwa ti pàãä fún wa.21 A sì ti gba àwün ìwé ìrántí

    nâ èyí tí Olúwa ti pàãä fúnwa, a sì ti yñ wõn wò fínni-fínnia sì ri wí pé wõn yä ní fífå;b∑ni, àní wõn jå iye nlá sí wa,níwÿn tí àwa fi lè ãe ìtõjúàwün òfin Olúwa fún àwünümü wa.22 Nítorí-èyi, ó jå ügbõn nínú

    Olúwa wí pé kí á gbé wün pñlúwa, bí a ãe n rin ìrìn-àjò nínú ijùsíhà ilñ ìlérí.

    ORI 6

    Nífáì kü nípa àwün ohun Ülõrun—Èrò Nífáì ni láti yí àwün ènìyànlõkàn padà láti wá sí ÿdÿ ÜlõrunÁbráhámù kí a sì gbà wõn là. Níìwÿn üdún 600 sí 592 kí á tó bíOlúwa wa.

    Àti nísisìyí èmi, Nífáì, kò küìtàn ìdílé àwün bàbá mi ni apáìwé ìrántí mi yî; b∑ni èmi kì yíòkü õ nígbà-kûgbà låhìn èyí sórí

    àwün àwo wÿnyí tí èmi n kü;nítorí ó ti wà nínú ìwé ìrántí èyítí bàbá mi ti pamõ; nítorí-èyi,èmi kò kü õ sínú iãå yî.

    2 Nítorí ó tó mi láti sü wí péàwa jå àtñlé Jósåfù.

    3 Kò sì jå ohunkóhun sí miwí pé kí èmi ãe àníyàn láti küñkún ìwé ìtàn gbogbo àwünnkan bàbá mi, nítorí wün kò ãeé kü sórí àwün àwo wÿnyí,nítorí mo få âyè kí èmi lè künípa àwün ohun Ülõrun.

    4 Nítorí ñkúnrårå èrò mi nikí èmi lè yí àwün ènìyàn lõkànpadà láti wá sí ÿdÿ ÜlõrunÁbráhámù, àti Ülõrun Ísâkì,àti Ülõrun Jákõbù, kí a sì gbàwõn là.

    5 Nítorí-èyi, àwün ohun èyí tíó ãe ìfå ti ayé èmi kò kü, ãùgbõnàwün ohun èyí tí ó ãé ìfå tiÜlõrun ati si awün wπnnì tí kîãe ti ayé.

    6 Nítorí-èyi, èmi yíò pa àãä fúnirú-ümü mi, pé àwün kò gbõdÿfi âyè gba àwün ohun tí kò níiye sí àwün ümü ènìyàn lóríàwün àwo wÿnyí.

    ORI 7

    Àwün ümükùnrin Léhì padà síJerúsálåmù wõn sì pe Íãmáålì àtiagbolé rñ láti darapÿ mõ wün ní ìrìnàjò wün — Lámánì àti àwün mírànãÿtñ—Nífáì gba àwün arákùnrin rñníyànjú láti ní ìgbàgbõ nínú Olúwa— Wõn dì í pñlú okùn wõn sì pèròìparun rñ —Ó di òmìnira nípaagbára ìgbàgbõ—Àwün arákùnrinrñ türü ìdáríjì — Léhì àti ÿwõ rñ rúäbü àti äbü-ürä sísun. Ní ìwÿn üdún600 sí 592 kí á tó bí Olúwa wa.

  • 11 1 Nífáì 7:1–16

    Àti nísisìyí èmi få kí ñyin lèmÿ wí pé låhìn tí bàbá mi,Léhì, ti fi òpin sí àsütålè nípairú-ümü rñ, ó ãe tí Olúwa tún wífún un, wí pé kò tõ fún un, Léhì,pé kí ó mú ìdílé rñ nìkan lüsínú ijù; ãùgbõn pé kí àwünümükùnrin rñ gbé àwün ümü-bìnrin ní aya, kí wün lè bímü síOlúwa ní ilñ ìlèrí.2 Ó sì ãe tí Olúwa pàãä fún

    un pé kí èmi, Nífáì, àti àwünarákùnrin mi, tún padà sí ilñJerúsálåmù, kí a sì mú Íãmáålìàti ìdílé rñ sÿkalñ wá sí ijù.3 Ó sì ãe tí èmi, Nífáì, pñlú àwün

    arákùnrin mi, tún jáde lü sínúijù láti gòkè lü sí Jerúsálåmù.4 Ó sì ãe tí a gòkè lü sí ile

    Íãmáålì, a sì rí ojúrere gbà ní-wájú Íãmáålì tób∑ tí a sü ÿrÿOlúwa fún un.5 Ó sì ãe tí Olúwa mú ükàn

    Íãmáålì rÿ, àti agbolé rñ pñlú,tób∑ tí wõn rin ìrìn-àjò wünsÿkalñ pñlú wa sínú ijù sí àgõbàbá wa.6 Ó sì ãe bí a ãe n rìn nínú

    ijù, kíyèsî Lámánì àti Låmúålì,àti méjì nínú àwün ümübìnrinÍãmáålì, àti àwün ümükùnrinÍãmáålì méjì àti àwün ìdílé wün,ãÿtñ sí wa; b∑ni sí èmi, Nífáì, àtiSâmú, àti bàbá wün, Íãmáålì,àti aya rñ, àti àwün ümübìnrinrñ míràn.7 Ó sì ãe nínú ÿtå èyí tí, wõn få

    láti padà sí ilñ Jerúsálåmù.8 Àti nísisìyí èmi, Nífáì, nítorí

    tí mo kådùn nítorí líle ükànwün, nítorínâ mo wí fún wün,wí pé, b∑ni, àní sí Lámánì àti síLåmúålì: Kíyèsî i ñyin jå ñgbõnmi, báwo ni tí ñyin sì ãe le báyîní ükàn yín, tí ä sì fõjú ní inú

    yín, tí ñyin få kí èmi, àbúrò yín,sÿrÿ sí yín, b∑ni, kí èmi sì gbéàpärä kalñ fún yín?

    9 Báwo ni tí ñyin kò fetísílñ síÿrÿ Olúwa?

    10 Báwo ni tí ñyin ti gbàgbé péñyin ti rí ángålì Olúwa kan?

    11 B∑ni, báwo sì ni tí ñyin tigbàgbé àwün ohun nlá tí Olúwati ãe fún wa, ní gbígbà wá kúròlõwõ Lábánì, àti pñlú tí àwa fi ríìwé ìrántí nâ gbà.

    12 B∑ni, báwo sì ni tí ñyin tigbàgbé pé Olúwa lè ãe ohungbogbo gågå bí ìfå rñ, fún àwünümü ènìyàn, bí ó bá ãe pé wõnlo ìgbàgbõ nínú rñ? Nítorí-èyi,ä jå kí á jå olóotõ sí i.

    13 Bí ó bá sì ãe pé àwa jå olóotõsí i, àwa yíò rí ilñ ìlérí gbà; ñyinyíò sì mÿ ní ìgbà kan tí nbÿpé ÿrÿ Olúwa yíò dí mímú ãänípa ìparun Jerúsálåmù; nítorígbogbo ohun tí Olúwa ti sü nípaìparun Jerúsálåmù ni gbüdÿ dimímú ãe.

    14 Nítorí kíyèsî i, Ñmí Olúwayíò dáwõ dúró láìpå láti máa báwün wÿjà; nítorí kíyèsî i, wõn tiãa àwün wòlî tì, Jeremíàh ni wõnsì ti jù sí inú túbú. Wõn sì ti wáÿnà láti mú ñmi bàbá mi kúrò,tób∑ tí wõn ti lé e jáde ní ilñ nâ.

    15 Nísisìyí kíyèsî i, mo süfún yín pé bí ñyin bá padà síJerúsálåmù ñyin nâ yíò ãègbépñlú wün. Àti nísisìyí, bí ñyin bání yíyàn, ä gòkè lü sí ilñ nâ, kí äsì rántí àwün ÿrÿ tí mo sü fúnyín, wí pé bí ñyin bá lü ñyin yíòãègbé pñlú; nítorí báyî ni ÑmíOlúwa rÿ mí pé kí èmi kí ó sü.

    16 Ó sì ãe nígbà tí èmi, Nífáì, tisü àwün ÿrÿ wÿnyí sí àwünarákùnrin mi, wõn bínú sí mi.

  • 1 Nífáì 7:17–8:8 12

    Ó sì ãe tí wõn gbá mi mú, nítoríkíyèsî i, wõn bínú lõpÿlüpÿ,wõn sì dì mí pñlú okùn, nítoríwõn wá láti mú ñmí mi kúrò, kíwõn lè fi mí sílñ sínú ijù kí àwünähànnà äranko lè pa mí jä.17 Ãùgbõn ó ãe tí mo gbàdúrà sí

    Olúwa, wípé: A! Olúwa, gågåbí ìgbàgbõ mí tí nbä nínú rä, njåìwü yíò gbà mí lõwõ àwün ará-kùnrin mi; b∑ni, àní kí o fúnmi ní agbára kí èmi lè já àwünèdídì wÿnyí èyí tí a fi dì mí.18 Ó sì ãe nígbà tí mo ti sü

    àwün ÿrÿ wÿnyí, kíyèsî i, àwünèdídì nâ túsílñ kúrò ní üwõàti äsñ mi, mo sì dúró níwájúàwün arákùnrin mi, mo sì túnsÿrÿ sí wün.19 Ó sì ãe tí wõn tún bínú sí mi,

    wõn sì wá ÿnà láti gbá mi mú;sùgbõn kíyèsî i, ÿkan nínú àwünümübìnrin Íãmáålì, b∑ni, àti ìyárñ pñlú, àti ÿkan nínú àwünümükùnrin Íãmáålì, ãìpñ sí àwünarákùnrin mi, tób∑ tí wõn múükàn wün rÿ; wõn sì dåkunlílépa láti mú ñmí mi kúrò.20 Ó sì ãe tí wõn kún fún

    ìbànújå, nítorí ìwà búburú wün,tób∑ tí wõn täríba níwájú mi,wõn sì ãìpñ sí mi pé kí èmi kíó dáríjì wün fún ohun tí wõn tiãe sí mi.21 Ó sì ãe tí mo dáríjì wõn ní

    ìfinúhàn, gbogbo ohun tí wõnti ãe, mo sì gbà wõn níyànjúpé kí wõn gbàdúrà sí OlúwaÜlõrun wün fún ìdáríjì. Ó sì ãetí wõn ãe b∑. Låhìn tí wõn sì tigbàdúrà tán sí Olúwa a tún rinìrìn-àjò wa síhà àgõ bàbá wa.22 Ó sì ãe tí a sÿkalñ sí àgõ

    bàbá mi. Låhìn tí èmi àti àwünarákùnrin mi àti gbogbo ilé

    Íãmáålì sì ti sÿkalñ sí àgõ babami, wõn ãe üpå sí Olúwa Ülõrunwün; wõn sì rú äbü àti äbü-üräsísun sí i.

    ORI 8

    Léhì rí ìran igi ìyè — Ó jä nínú èsorñ ó sì få kí ìdílé òun ãe b∑gågå —Ó rí ÿpá irin kan, ÿnà híhá àti tôrókan, àti òkùnkùn biribiri tí ó bòènìyàn — Sáráíà, Nífáì, àti Sâmújä nínú èso nâ, ãùgbõn Lámánì àtiLåmúålì kÿ. Ní ìwÿn üdún 600 sí592 kí á tó bí Olúwa wa.

    Ó sì ãe tí a ti kó onírúurú irúgbìnoríãiríãi jü lákôpÿ, àti ti oríãirí-ãi wóró irúgbìn, àti ti oríãiríãiirúgbìn èso pñlú.

    2 Ó sì ãe nígbà tí bàbá mi dúró-låhìn nínú ijù ó wí fún wa, wípé: Kíyèsî i, mo ti lá àlá kan, tàbíní ÿnà míràn, mo ti rí ìran kan.

    3 Sì kíyèsî i, nítorí ohun tí mo tirí, mo ní ìdí láti yÿ nínú Olúwanítorí ti Nífáì àti Sâmú pñlú;nítorí tí mo ní ìdí láti rò péàwün, àti púpÿ nínú irú-ümüwün pñlú, ni a ó gbàlà.

    4 Ãùgbõn kíyèsî i, Lámánìàti Låmúålì, mo bñrù lõpÿlüpÿnítorí yín; nítorí kíyèsî i, mo ròpé mo ri nínú àlá mi, ijù kan tí óãókùnkùn tí ó sì binújå.

    5 Ó sì ãe tí mo rí ükùnrin kan,ó sì wü ñwù funfun kan, ó sì wádúró níwájú mi.

    6 Ó sì ãe tí ó sÿrÿ sí mi, ó sì pèmí kí n tñlé òun.

    7 Ó sì ãe bí mo ãe n tñlé e mo ríara mi pé mo wá nínú ahorokan tí ó ãókùnkùn tí ó sì binújå.

    8 Låhìn tí mo sì ti rin ìrìn-àjòfún ìwÿn ÿpÿlüpÿ wákàtí nínú

  • 13 1 Nífáì 8:9–27

    òkùnkùn, mo bñrñ sí gbàdúrà síOlúwa wí pé kí ó ní ânú lórí mi,gågå bí ÿpÿlüpÿ ìrünú ânú rñ.9 Ó sì ãe låhìn tí mo ti gbàdúrà

    sí Olúwa mo rí pápá kan tí ó tóbití ó sì gbôrò.10 Ó sì ãe tí mo rí igi kan,

    èso èyí tí o yä ní fífå láti múinú äni dùn.11 Ó sì ãe tí mo jáde lü mo sì

    jä nínú èso rñ; mo sì ri wí pé ódùn réküjá, ju gbogbo ohun tímo ti tõwò rí. B∑ni, mo sì ri wípé èso rñ jå funfun, tí ó tayügbogbo fífunfun tí mo ti rí rí.12 Bí mo sì ti jä nínú èso rñ ó

    fi ayÿ nlá tí ó réküjá kún ükànmi; nítorínâ, mo bñrñ sí ní ìfå wípé kí ìdílé mi kí ó jä nínú rñpñlú; nítorí mo mÿ wí pé ó yä nífífå ju gbogbo èso míràn.13 Bí mo sì ti gbé ojú mi yíká

    kâkiri pé bóyá mo lè wá ìdílé mirí pñlú, mo rí odò omi kan, ó sìn ãàn lü, ó sì wà nítòsí igi èyí tímÿ n jä èso rñ.14 Mo sì wò láti rí ibi tí ó ti wá;

    mo sì rí orísun rñ níwájú díñ;níbi orísun nâ mo sì rí ìyá räSáráíà, àti Sâmú, àti Nífáì; wõnsì dúró bí pé wün kò mõ ibi tíwün yíò lü.15 Ó sì ãe mo juwõ sí wün; mo

    sì tún sü fún wün pñlú ohùnkíkan wí pé kí wõn wá sí ÿdÿmi, kí wõn jä nínú èso nâ, èyí tíó yä ní fífå ju gbogbo èso míràn.16 Ó sì ãe tí wõn wá sí ÿdÿ mi

    tí wõn sì jä nínú èso nâ pñlú.17 Ó sì ãe tí mo ní ìfå wí pé kí

    Lámánì àti Låmúålì wá jä nínúèso nâ pñlú; nítorínâ, mo gbéojú mi síhà orísun odò nâ, wípé bóyá mo lè rí wün.18 Ó sì ãe tí mo rí wün, ãùgbõn

    wün kò wá sí ÿdÿ mi kí wõn sìjä nínú èso nâ.

    19 Mo sì rí ÿpá irin kan, ósì gùn lü lågb∑ bèbè odò nâ,ó sì gùn dé ibi igi ní ñbá èyítí mo dúró.

    20 Mo sì tún rí ÿnà híhá àti tôrókan, èyí tí ó wà lågb∑ ÿpá irinnâ, títí fi dé ibi igi ñbá èyí tímo dúró; ó sì gùn küjá orísunnâ pñlú, títí dé pápá kan tí ótóbi tí ó sì gbôrò, bí äni pé ójå ayé kan.

    21 Mo sì rí àjü àìníye àwünènìyàn, ÿpÿ èyí tí ó n tñ síwájú,kí wõn lè dé ÿnà nâ èyí tí ó lüsí ibi igi ni ñbá èyí tí mo dúró.

    22 Ó sì ãe tí wõn jáde wá, tíwõn sì bñrñ sí rìn ní ÿnà èyí tíó lü sí ibi igi nâ.

    23 Ó sì ãe tí òkùnkùn biribiriyü jáde; b∑ni, àní òkùnkùnbiribiri nlá lõpÿlüpÿ, tób∑ tíàwün tí wõn ti bñrñ sí rìn níÿnà nâ ãìnà, tí wõn ãáko kúrò tíwõn sì sünù.

    24 Ó sì ãe tí mo rí àwün míràntí wõn n tñ síwájú, wõn sì jádewá wõn sì di ìdí ÿpá irin nâ mú;wõn sì tñ síwájú lârín òkùnkùnbiribiri nâ, wõn rÿ mõ ÿpá irinnâ, àní títí tí wõn fi jáde wá tíwõn sì jä nínú èso igi nâ.

    25 Låhìn tí wõn sì ti jä nínú èsoigi nâ wõn gbé ojú wün yíkâkiribí äni pé wõn n tijú.

    26 Mo sì tún gbé ojú mi yíkákâkiri, mo sì ãàkíyèsí ilé nlá kantí o sì gbôrò ní òdì kejì odòomi nâ; ó sì dàbí pé ó dúró níòfúrufú, tí ó ga lórí ilñ.

    27 Ó sì kún fún ènìyàn, àti ogbóàti ÿdõ, àti ükùnrin àti obìnrin;ìmúra wün sì dára lõpÿlüpÿ;wõn sì wà ní ìãesí fífi ãe älåyà

  • 1 Nífáì 8:28–9:4 14

    àti nína ìka üwõ síhà àwün tíwõn ti wá tí wõn sì n jä èso nâ.28 Låhìn tí wõn sì ti tõ èso nâ

    wò ojú tì wõn, nítorí àwün tí ón kågàn wün; wõn sì ãáko lüsínú àwün ÿnà tí a kà lêwÿ wõnsì sünù.29 Àti nísisìyí èmi, Nífáì, kò sü

    gbogbo àwün ÿrÿ bàbá mi.30 Ãùgbõn, kí n lè ké ìwé mi

    kúrú, kíyèsî i, ó rí ÿgπrÿ ènìyànmíràn tí wõn n tñ síwájú, wõn sìwá wõn sì di ìdí ÿpá irin nâ mú;wõn sì tñ síwájú lõnà wün, wõnn di ÿpá irin nâ mú ãinãin títí lü,títí wõn fi jáde wá tí wõn wólulñtí wõn sì jä nínú èso igi nâ.31 Ó sì tún rí ÿgπrÿ ènìyàn

    míràn tí wõn n füwõwá ÿnà wünsíhà ilé nlá tí ó sì gbôrò nì.32 Ó sì ãe ÿpÿlüpÿ ni ó rì sínú

    omi nínú ibú orísun nâ; ÿpÿ nió sì sünù tí kò rí mõ, tí wõn nãáko ní awün ÿnà tí ó ãàjèjì.33 Ÿgπrÿ ènìyàn nâ sì pÿ tí ó

    wü inú ilé tí ó ãàjèjì nì. Låhìn tíwõn sì wü inú ilé nì wõn na ìkaüwõ ñgàn sí èmi àti àwün tí ó njä nínú èso nâ pñlú; ãùgbõn àwakò kíyèsî wün.34 Ìwÿnyí ni àwün ÿrÿ bàbá mi:

    Nítorí gbogbo àwün tí ó kíyèsîwün ni ó ti ãáko.35 Lámánì àti Låmúålì kò sì jä

    nínú èso nâ, b∑ni bàbá mi sü.36 Ó sì ãe låhìn tí bàbá mi ti

    sü gbogbo àwün ÿrÿ àlá tàbíìran rñ, èyí tí ó pÿ, ó sü fún wa,nítorí àwün ohun wÿnyí tí ó rínínú ìran, ó bñrù lõpÿlüpÿ fúnLámánì àti Låmúålì; b∑ni, óbñrù kí a máãe ta wõn nù kúròníwájú Olúwa.37 Ó sì gbà wõn níyànjú nígbà

    nâ pñlú gbogbo ìmÿ òbí tí ó

    ãàníyàn, pé kí wõn fetí sí àwünÿrÿ rñ, pé bóyá Olúwa yíò niânú sí wün, tí kì yíò sì ta wõnnù; b∑ni, bàbá mi wâsù sí wün.

    38 Låhìn tí ó sì ti wâsù sí wün,tí ó sì sütålñ sí wün pñlú nípaÿpÿlüpÿ ohun, o rÿ wõn látipa òfin Olúwa mõ; ó sì dåkunsísÿrÿ sí wün.

    ORI 9

    Nífáì ãe ìwé ìrántí sí ÿnà méjì —À n pe ÿkπkan ní àwün àwo tiNífáì — Àwün àwo nlá ní ìwé ìtànti ayé nínú; àwün kékeré nî ãe pñlúàwün ohun mímõ. Níwÿn üdún600 sí 592 kí á tó bí Olúwa wa.

    Gbogbo àwün ohun wÿnyí sìni bàbá mi rí, tí ó sì gbõ, tí ósì sü, bí ó ãe gbé nínú àgõ,ní àfonífojì Låmúålì, àti pñlúÿpÿlüpÿ ohun nlá sí i, èyí tí kòãe é kü sórí àwün àwo wÿnyí.

    2 Àti nísisìyí gågå bí mo ti sünípa àwün àwo wÿnyí, kíyèsî iwün kì í ãe àwün àwo èyí tí moãe kíkún ìwé ìtàn ti ìrántí àwünènìyàn mi sórí wün; nítorí àwünàwo èyí tí mo ãe ìwé ìtàn kíkúnàwün ènìyàn mi sórí wün ni moti fún ní orúkü Nífáì; nítorí-èyi,à n pè wõn ní àwün àwo ti Nífáì,ní àpètñlé orúkü tèmi; àwünàwo wÿnyí sì ni à n pè ní àwünàwo ti Nífáì.

    3 Bíótilñríb∑, mo ti gba àãälõwõ Olúwa pé kí èmi kí ó ãeàwün àwo wÿnyí, fún àkànãe ètepé kí ìwé ìtàn tí a fín nípa ti iãåìránãå àwün ènìyàn mi le wà.

    4 Lórí àwün àwo kejì ni kí afín ìwé ìtàn ìjüba àwün übasí, àti àwün ogun àti ìjà àwün

  • 15 1 Nífáì 9:5–10:10

    ènìyàn mi; nítorí-èyi àwün àwowÿnyí wà fún èyí tí ó pÿjù ní iãåìránãå nâ; àwün àwo kejì sì wàfún èyí tí ó pÿjù ní ìjüba àwünüba àti àwün ogun àti ìjà àwünènìyàn mi.5 Nítorí-èyi Olúwa ti pàãä

    fún mi láti ãe àwün àwo wÿnyífún ète òye nínú rñ, ète èyítí èmi kò mÿ.6 Ãùgbõn Olúwa mõ ohun

    gbogbo láti ìbñrñ; nítorí-èyi, ópèsè ÿnà láti ãe gbogbo iãå rñparí lârín àwün ümü ènìyàn;nítorí kíyèsî i, ó ní gbogboagbára sí mímú gbogbo ÿrÿ rñãä. Báyî ni ó sì rí. Àmín.

    ORI 10

    Léhì sütålñ pé àwün Jû ni a ó múní ìgbèkùn nípasñ àwün aráBábílõnì — Ó sü nípa bíbÿ Messiakan, Olùgbàlà àti Olùràpadà lârínàwün Jû — Léhì sü pñlú nípa bíbÿäni tí yíò rì Ÿdõ-àgùtàn Ülõrunn â b ü m i — L é h ì s ü n í p a i k úàti àjínde òkú ti Messia nâ — Ófi títúká àti kíkójü Ísráålì wé igiólífì — Nífáì sü nípa Ümü Ülõrun,nípa ñbùn Ñmí Mímõ, àti nípa ãíãeòdodo. Ní ìwÿn üdún 600 sí 592kí á tó bí Olúwa wa.

    Àti nísisìyí èmi, Nífáì tñ síwájúláti kü ìwé ìtàn àwün íãe mi, àtiìjüba àti iãå ìránãå mi sórí àwünàwo wÿnyí; nítorí-èyi, láti tñsíwájú pñlú ìwé ìtàn tèmi, mogbõdÿ sÿrÿ díñ nípa àwünohun ti bàbá mi, àti ti àwün ará-kùnrin mi pñlú.2 Nítorí kíyèsî i, ó ãe låhìn tí

    bàbá mi ti parí sísü àwün ÿrÿàlá rñ, àti gbígbà wõn níyànjú sí

    âpün ní ohun gbogbo pñlú, ó wífún wün nípa àwün Jû —

    3 Wí pé låhìn tí a bá pa wõnrun, àní Jerúsálåmù ìlú nlá nì,tí a sì tí mú ÿpÿlüpÿ ní ìgbèkùnlü sí Bábílõnì, gågå bí àkókò tíó yä níti Olúwa, wün yíò túnpadà, b∑ni, àní a ó mú wün padàjáde ní ìgbèkun; låhìn tí a bá sìmú wün padà jáde ní ìgbèkunwün yíò tún gba ilñ ìní wün.

    4 B∑ni, àní ní ägbñta üdúnsí ìgbà tí bàbá mi kúrò níJerúsálåmù, wòlî kan ni OlúwaÜlõrun yíò gbé dìde lârín àwünJû—àní Messia kan, tàbí, ní ÿnàmíràn, Olùgbàlà ayé.

    5 Ó sì sÿrÿ pñlú nípa àwünwòlî, bí púpÿ ní iye wün ti jårî síàwün ohun wÿnyí, nípa Messiayî, äni tí òun ti sÿrÿ nípa rñ, tàbíOlùràpadà ayé yî.

    6 Nítorí-èyi, gbogbo aráyé wàní ipò ìsünù àti ti ìãubú, wün ó sìwà b∑ láé àfi tí wõn bá gbíyèléOlùràpadà yî.

    7 Ó sì wí nípa wòlî kan äni tíyíò wá ãíwáju Messia nâ, láti túnÿnà Olúwa ãe —

    8 B∑ni, àní òun yíò jáde lü yíò sìkígbe ní ijù: Ä tún ÿnà Olúwa ãe,ä sì ãe ojú-ÿnà rñ tõ; nítorí ÿkandúró lârín yín äni tí ñyin kò mÿ;òun sì lágbára jù mí lü, okùnbàtà äsñ äni tí èmi kò yä láti tú.Púpÿ sì ni ohun tí bàbá mi sünípa nkan yî.

    9 Bàbá mi sì sü wí pé yíò rìni-bümi ní Bätabárà, níküjá Jordánì;ó sì sü pñlú pé yíò rìnibümi pñlúomi, àní wí pé yíò ãe ìrìbümifun Messia nâ pñlú omi.

    10 Àti låhìn tí ó bá ti ãe ìrìbümifun Messia nâ pñlú omi, yíòjåwõ yíò sì jårî wí pé òun ti ri

  • 1 Nífáì 10:11–22 16

    Ÿdõ-àgùtàn Ülõrun bümi, änití yíò mú ñsñ ayé lü.11 Ó sì ãe låhìn tí bàbá mi ti

    sü àwün ÿrÿ wÿnyí, ó sÿrÿsí àwün arákùnrin mi nípaìhìn-rere èyí tí a ó wâsù lârínàwün Jû, àti pñlú nípa rirähinàwün Jû nínú ìgbàgbõ. Låhìntí wõn bá ti pa Messia nâ, änití yíò wá, låhìn tí a bá sì ti paá òun yíò jínde kúrò nínú òkú,yíò sì fi ara rñ hàn, nípasñ ÑmíMímõ, sí àwün Kèfèrì.12 B∑ni, àní bàbá mi sÿrÿ púpÿ

    nípa àwün Kèfèrí àti nípa aráilé Ísráålì pñlú, wí pé wün yíò ríbí igi ólífì, ñka èyí tí a ó ãå kúròtí a ó sì túká sórí gbogbo ojú-ilñàgbáyé.13 Nítorí-èyi, ó sü pé ó ãe

    dandan pé kí a tõ wa pñlú ükànkan sínú ilñ ìlérí sí mímú ÿrÿOlúwa ãä, wípé a ó tú wa kásórí gbogbo ojú-ilñ àgbáyé.14 Låhìn tí a bá sì ti tú ará

    ilé Ísráålì ká a ó tún kó wünjü; tàbí, ní ãókí, låhìn tí àwünKèfèrí bá ti gba ñkún Ìhìn-rereäká àdánidá igi ólífi nâ, tàbíàwün ìyókù ará ilé Ísráålì, ni aó lõ sínú igi nâ, tàbí wá sí ìmÿMessia òtítõ, Olúwa wün àtiOlùràpadà wün.15 Irú èdè báyî sì ni bàbá mi

    fi sütålñ tí ó sì sÿrÿ sí àwün ará-kùnrin mi, àti ÿpÿlüpÿ ohun síi pñlú èyí tí èmi kò kü sínú ìwéyî; nítorí ó ti kü púpÿ tí ó jå yíyäfún mi nínú ìwé mi míràn.16 Gbogbo àwün nkan wÿnyí,

    èyí tí mo ti sÿrÿ nípa rñ, ni a sìãe nígbà tí bàbá mi n gbé nínúàgõ, ní àfonífojì Låmúålì.17 Ó sì ãe låhìn tí èmi, Nífáì, tí

    mo ti gbõ gbogbo àwün ÿrÿ

    bàbá mi, nípa àwün ohun tí ó rínínú ìran, àti pñlú àwün ohun tíó sü nípasñ agbára Ñmí Mímõ,agbára èyí tí ó gbà nípasñìgbàgbõ nínú Ümü Ülõrun —Ümü Ülõrun nâ sì jå Messia tíyíò wá—èmi, Nífáì, nífä pñlú pékí èmi lè rí, kí n gbõ, kí n sì mÿnípa àwün nkan wÿnyí, nípasñagbára Ñmí Mímõ, èyí tí ó jåñbùn Ülõrun fún gbogbo àwüntí ó bá wá a lójúméjêjì, gågå bí tiìgbà àtijõ àti bí ti ìgbà tí yíò fiara rñ hàn sí àwün ümü ènìyàn.

    18 Nítorí ó jå ÿkan nâ ní áná, níóní, àti títí láé; a sì ti pèsè ÿnàfún gbogbo ènìyàn láti ìpilñãñayé wa, bí ó bá ãe pé wõn ro-núpìwàdà tí wõn sì wá sí ÿdÿ rñ.

    19 Nítorí äni tí ó bá wá lójúmé-jêjì yíò rí; ohun ìjìnlñ Ülõrun ni aó sì fihàn sí wün, nípasñ agbáraÑmí Mímõ, ní ìgbà yí gågå bíìgbà àtijõ, àti gågå bí ìgbààtijõ bí ìgbà tí nbü; nítorí-èyiipa ÿnà Olúwa jå ÿnà àìyípadàayérayé kan.

    20 Nítorínâ rántí, A! ümü ènì-yàn, fún gbogbo ìãe rä a o mú üwá sínú ìdájõ.

    21 Nítorí-èyi, bí ìwü bá ti wá látiãe búburú ní ìgbà ayé-ìdánwòrä, njå a ó rí ü ní àìmõ níwájúìtå ìdájõ Ülõrun; ohun àìmõkan kò sì lè gbé pñlú Ülõrun;nítorí-èyi a ó ta õ nù títí láé.

    22 Ñmí Mímõ sì fún mi ní àãäpe ki n sü àwün nkan wÿnyí, kín má si ãe så wün.

    ORI 11

    Nífáì rí Ñmí Olúwa, a sì fi igi ìyèhàn á ní ojúran — Ó rí ìyá Ümü

  • 17 1 Nífáì 11:1–18

    Ülõrun ó sì kõ ñkõ nípa ìrä-ara-sílñti Ülõrun — Ó rí ìrìbümi, iãåìránãå, áti ìkànmõ àgbélèbú tiŸdõ-àgùtàn Ülõrun — Ó rí ìpè àtiiãå ìránãå ti àwün Àpóstélì Méjìláti Ÿdõ-àgùtàn pñlú. Ní ìwÿn üdún600 sí 592 kí á tó bí Olúwa wa.

    Nítorí ó sì ãe låhìn tí mo tifå láti mõ àwün ohun tí bàbámi ti rí, tí mo sì gbàgbõ wípéOlúwa lè sü wõn di mímÿ fúnmi, bí mo ãe jóko tí mÿ nrò nínúükàn mi, a mú mi lü nínú ÑmíOlúwa, b∑ni, sí òkè gíga gan-an,èyí tí èmi kò tí ì rí rí, orí èyí tíèmi kò sì tí tñ rí.2 Ñmí nâ sì sü fún mi: Kíyèsî,

    kíni ìwü nfå?3 Mo sì wípé: Mo få láti rí àwün

    ohun tí bàbá mi rí.4 Ñmí nâ sì sü fún mi: Njå ìwü

    gbàgbõ pé bàbá rä rí igi èyí tí óti sÿrÿ nípa rñ?5 Mo sì wípé: B∑ni, ìwü mÿ

    wípé mo gba gbogbo àwün ÿrÿbàbá mi gbõ.6 Nígbàtí mo sì sü àwün ÿrÿ

    wÿnyí, Ñmí nâ kígbe pñlúohùn rara, wípé: Hòsánnà síOlúwa, Ülõrun änití-ó-gá-jùlü;nítorítí ó jå Ülõrun lórí gbogboayé, b∑ni, àní ga ju ohun gbo-gbo lü. Alábùkún-fún sì ni ìwü,Nífáì, nítorítí ìwü gbàgbõ nínúÜmü Ülõrun änití-ó-gá-jùlü;Nítorínâ ìwü yíò rí àwün ohuntí ìwü nfå.7 Sì kíyèsî i nkàn yí ni a ó fi

    fún ü fún àmì, pé låhìn tí ìwübá ti rí igi èyí tí ó so èso èyítí bàbá rä tõwò, ìwü yíò ríükùnrin kan pñlú tí ó nsÿkalñjáde láti ÿrun, òun sì ni ìwüyíò ãe lårî; låhìn tí ìwü bá sì ti

    jårî rñ ìwü yíò jårî pe ó jå ÜmüÜlõrun.

    8 Ó sì ãe tí Ñmí ná à wí fún mi:Wò ó! Mo si wò ó, mo sì kíyèsîigi kan; ó sì dàbí igi èyítí bàbá miti rí; äwà rñ sì réküjá jìnà, b∑ni,tayü gbogbo äwà; funfun rñ sìtayü funfun ìrì dídì tí afåfå kójü.

    9 Ó sì ãe låhìn tí mo ti rí iginâ, mo wí fún Ñmí nâ: Mo kíyè-sî pé ìwü ti fi igi èyítí ó níye lóríga ju gbogbo ohun lü hàn mí.

    10 Ó sì wí fún mi: Kíni ìwü få?11 Mo sì wí fún un: Láti mõ

    ìtumÿ èyínâ — nítorí mo bá asÿrÿ bí ènìyàn ãe nsÿrÿ; nítorímo kíyèsî i wípé ó wà ní ìwoti ènìyàn; sùgbõn bíótilñríb∑,mo mÿ wípé Ñmí Olúwa ni; ósì bá mi sÿrÿ bí ènìyàn kan ãenbá òmíràn sÿrÿ.

    12 Ó sì ãe tí ó sü fún mi: Wò ó!Mo sì wò bí äni pé kí n wò ó,èmi kò sì rí i; nítorí ó ti lü kúròníwájú mi.

    13 Ó sì ãe tí mo wò tí mo sìrí ìlú-nlá Jerúsálåmù nì, àtiàwün ìlú-nlá míràn pñlú. Mo sìrí ìlú-nlá Násáråtì; ní ìlú-nláNásáråtì mo sì rí wúndíá kan,ó sì dára, ó sì funfun lõpÿlüpÿ.

    14 Ó sì ãe tí mo rí ÿrun tí ó ãísílñ; angålì kan sì sÿkalñ ó sìdúró níwájú mi; ó sì wí fún mi:Nífáì, kíni ìwü rí?

    15 Mo sì wí fún un: Wúndíákan, tí ó låwà tí ó sì dára jugbogbo àwün wúndíá míràn lü.

    16 Ó sì wí fún mi: Njå ìwü mõìrä-ara-sílñ ti Ülõrun?

    17 Mo sì wí fún un: Mo mÿwípé ó fåràn àwün ümü rñ;bíótilñríb∑, èmi kò mõ ìtúmÿohun gbogbo.

    18 Ó sì wí fún mi: Kíyèsî,

  • 1 Nífáì 11:19–34 18

    wúndíá tí ìwü rí nì jå ìyá ÜmüÜlõrun, gågåbí ti äran ara.19 Ó sì ãe tí mo rí tí a mú u

    lü nínú Ñmí; låhìn tí a sì ti múu lü nínú Ñmí ní ìwÿn ìgbàdíñ, angålì ná à bá mi sÿrÿ,wípé: Wò ó!20 Mo sì wò mo sì tún kíyèsî

    wúndíá ná à, ó gbé ümü kan níüwõ rñ.21 Angålì nâ sì wí fún mi: Wo

    Ÿdõ-àgùtan Ülõrun, b∑ni, àníÜmü Bàbá Ayérayé! Njå ìwümõ ìtumÿ igi èyí tí bàbá rä rí?22 Mo sì dá a lóhùn wípé:

    B∑ni, ó jå ìfå Ülõrun, èyítí ó tanara rñ ká lóde nínú ükàn àwünümü ènìyàn; nítorínâ, ó jå ohunti o wuni ju gbogbo ohun lü.23 Ó sì bá mi sÿrÿ, wípé:

    B∑ni, àti tí o ãe inú dídùn jùlüfún ükàn.24 Låhìn tí ó sì ti sü àwün ÿrÿ

    wÿnyí, ó wí fún mi: Wò ó! Mo sìwò, mo sì rí Ümü Ülõrun tí ó nkâkiri lârín àwün ümü ènìyàn;mo sì rí ÿpÿlüpÿ tí wõn wolñ níäsñ rñ tí wõn sì foríbalñ fún un.25 Ó sì ãe tí mo rí wípé ÿpá irin

    nâ, èyí tí bàbá mi ti rí, jå ÿrÿÜlõrun, èyí tí ó tõni sí orísunomi ìyè, tàbí sí igi ìyè; omi èyítí ó jå àpärä ìfå Ülõrun; mosi tún rí i wípé igi ìyè nâ jåàpärä ìfå Ülõrun.26 Angålì ná à sì tún wí fún mi:

    Wò kí o sì ri ìrä-ara-sílñ Ülõrun!27 Mo sì wò mo sì rí Olùràpa-

    dà ayé, äni tí bàbá mi ti sÿrÿnípa rñ; mo sì tún rí wòlî nâ änití yíò tún ÿnà ãe ãíwájú rñ.Ÿdõ-àgùtàn Ülõrun ná à sì jádelü a s ì r ì i bümi nípa üwõrñ; Låhìn tí a sì rìbümi rñ, mo ríÿrun tí ó ãí sílñ, Ñmí Mímõ sì

    sÿkalñ láti ÿrun wá, ó sì bà sórírñ ní àwÿ àdàbà.

    28 Mo sì rí i wípé ó jáde lü ón ãe ìránãå fún àwün ènìyàn, níagbára àti ògo nlá; ÿpÿ ènìyànsì jùmÿ péjü láti gbõ ü; mo sìrí i wípé wõn lée jáde kúròlârín wün.

    29 Mo sì tún rí àwün méjìlámíràn tí wõn ntñlé e. Ó sì ãetí a mú wün lü nínú Ñmí kúròníwájú mi, èmi kò sì rí wün.

    30 Ó sì ãe tí ángåli ná à túnbá mi sÿrÿ, wípé: Wò ó! Mo sìwò, mo sì kíyèsí àwün ÿruntí wõn tún ãí sílñ, mo sì rí àwünángålì tí wõn nsÿkalñ sórí àwünümü ènìyàn; wõn sì ãe iså ìránãåfún wün.

    31 Ó sì tún bá mi sÿrÿ, wípé:Wò ó! Mo sì wò, mo sì kíyèsíŸdõ-àgùtàn Ülõrun tí ó nkâkirilârín àwün ümü ènìyàn. Mo sìkíyèsí ÿpÿlüpÿ ènìyàn tí wõnnãàìsàn, tí a sì põn-lójú pñlúonírûrú àrùn gbogbo, àti pñlúàwün èãù àti àwün ñmí àìmõ;angålì nâ sì sü, ó sì fi gbogboàwün nkan wÿnyí hàn mí. Wõnsì rí ìwòsàn nípasñ agbára Ÿdõ-àgùtàn Ülõrun; àwün èãù àtiàwün ñmí àìmõ ni a sì lé jáde.

    32 Ó sì ãe tí angålì ná à túnbá mi sÿrÿ, wípé: Wò ó! Mosì wò mo sì kíyèsí Ÿdõ-àgùtànÜlõrun, tí àwün ènìyàn múu; b∑ni, Ümü Ülõrun títí ayéni a dáléjõ nípa ayé; mo sì rí mosì jårî.

    33 Èmi, Nífáì, sì ri i tí a gbé esókè sórí àgbélèbú tí a sì pa áfún àwün ñãñ ayé.

    34 Låhìn tí a sì ti pa á, mo rí ÿpÿènìyàn ayé, tí wõn jùmÿ péjülati dojú ìjà kü àwün àpóstélì

  • 19 1 Nífáì 11:35–12:9

    Ÿdõ-àgùtàn; nítorí báyî ni an-gålì Olúwa pe àwün méjìlá nâ.35 Ÿpÿ ènìyan ayé sì jùmÿ

    péjü; mo sì kíyèsí pé wõn wànínú ilé kan tí ó tóbi tí ó sì gbô-rò, tí o dàbí ilé èyí tí bàbá mi rí.Angålì Olúwa ná à sì tún bá misÿrÿ, wípé: Kíyèsí ayé àt iügbõn inú rñ; b∑ni, kíyèsî aráilé Isráålì ti jùmÿ péjü láti dojúìjà kü àwün àpóstélì méjìlá tiŸdõ-àgùtàn.

    36 Ó sì ãe tí mo rí tí mo sì jårî,pé ilé tí ó tóbi tí ó sì gbôrò nâ jåìgbéraga ayé; ó sì wó, wíwó rñsì pÿ lõpÿlüpÿ. Angålì Olúwa náà sì tún bá mi sÿrÿ, wípé: Báyî niìparun gbogbo àwün orílñ-èdè,ìbátan, èdè àti ènìyàn yíò rí, tíyíò dojú ìjà kü àwün àpóstélìméjìlá ti Ÿdõ-àgùtàn.

    ORI 12

    Nífáì rí ilñ ìlérí nínú ìran; ó ríòdodo, àìãedêdé, àti ìãubú àwünolùgbé rñ; bíbÿ Ÿdõ-àgùtàn Ülõrunlârín wün; bí àwün Ümü-ñhìn mé-jêjìlá àti àwün Àpóstélì méjêjìláyíò ãe ìdájõ fún Isráålì; àti ipòälågbin àti elêrí àwün tí wõn rñhìnnínú ìgbàgbõ. Ní ìwÿn üdún 600sí 592 kí á tó bí Olúwa wa.

    Ó sí ãe tí angålì ná à wí fún mi:Wò ó, sì kíyèsí irú-ümü rä, àtiirú-ümü arákùnrin rä pñlú. Mosì wò mo sì kíyèsí ilñ ìlérí náà; mo sì kíyèsí ÿpÿlüpÿ ènìyàn,b∑ni, àní bí ó ti rí ní iye, tí wünpÿ bí iyanrìn òkun.2 Ó sì ãe tí mo kíyèsí ÿpÿ ènì-

    yàn tí wõn kórajü láti jagun, tíÿkan ndojúkü èkejì; mo sì kíyè-s í ogun, à t i ìdàgìr ì ogun,

    àti ìpakúpa nlá pñlú idà lârínàwün ènìyan mi.

    3 Ó sì ãe tí mo kíyèsí ÿpÿlüpÿìran tí ó réküjá, nípasñ ÿnà àwünogun àti àwün ìjà ní ilñ nâ; mosì kíyèsí ÿpÿlüpÿ àwün ìlú-nlá,b∑ni, àní tí n kò ka iye wün.

    4 Ó sì ãe tí mo rí ìkûku níojú ilñ ìlérí; mo sì rí àwün mÿ-nàmõná, mo sì gbõ sísán àwünàrá, àti ilñ rírì àti gbogbo oníru-rú àwün ariwo rúdurùdu; mosì rí ilñ àti àwün àpáta, tí wõns á n ; m o s ì r í à w ü n ò k